Tiwalola Olanubi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Tiwalola Olanubi

Tiwalola Olanubi Jnr tí wọ́n bí ní ọjọ́ kejìdílọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 1988 jẹ́ olókowò ara ẹni lórí oúnjẹ, oníṣẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1][2][3]

Òun ni olùdásílẹ̀ ilé-iṣ́ẹ́ Dotts Media House èyí tí ó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ilé-iṣẹ́ tí ó lààmì-laaka ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ nípa digital marketing, òun náà tún ni olùdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ '' Zarafet Loaves'' tí ó jẹ́ ilé-iṣẹ́ búrẹ́dì tí ó wà ní ilú Èkó, òun náà tún ni olùdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ Trendupp Africa. Òun náà tún ni Olóòtú àgbà ìwé ''Nigerian Influencer Marketing Report'' (NIMR).[4]̀[5]

Àwọn ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Chinyere Eze (10 May 2019). "Young Nigerian Entrepreneur, Tiwalola Olanubi an exemplary to his peers". News Direct 5 (  127): 4. 
  2. Francis Okoliko (August 27, 2019). "Tiwalola Olanubi Jnr Nominated for Future Award 2nd time in three years". Daily Asset 6 (  215): 29. ISSN 2616-1036. 
  3. Admin. "TIWALOLA OLANUBI JNR – OUR REBRAND NIGERIA AMBASSADOR | Rebrand Nigeria Campaign" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2020-06-04. Retrieved 2020-06-04. 
  4. "Dotts Media emerges best digital, marketing influencer in 2019". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-12-27. Retrieved 2021-05-26. 
  5. BellaNaija.com (2020-03-16). "Tiwalola Olanubi Jnr. of DottsMediaHouse is Our #BellaNaijaMCM this Week!". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-05-26.