Àrá kangúdù

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

'Síkírù Adéṣínà tí ó lògbà láàrin ọdún 1971 sí ọjọ́ kẹjọ, oṣù Kejì Ọdún,2016), tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ sí Àrákangúdù, jẹ́ òṣèré omo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó tún jẹ́ Olùdarí àti olóòtú sinimá. [1] Ó jẹ́ gbajúgbajà nípa kí kópa gégé bí Oníṣègùn, Ọlọ́ṣà tàbí ògbóǹtarìgì Aláwo nínú àwọn fíìmù tí ó ti kópa.[2]Ní ọjọ kẹjọ, oṣù Kejì Ọdún Ẹgbàá-lé-mẹ́ẹ̀dógún ni ọ ṣàìsí ní ilé rẹ ní Kaduna, apá ìha àríwá Nàìjíríà.[3][4]

Àwọn fíìmù tí ó ti kópa[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Tèmi Ni, Tì ẹ Kọ́
  • Ìdùnú Mi
  • Ìlù Gángan
  • Ògbólògbó
  • Ìyà Ojú Ogun
  • Èrè Àgbèrè
  • Àgbẹ̀dẹ Ògún
  • Àgbà Òṣùgbó
  • Ajé Olókun
  • Ìyá Ọkọ Bournvita
  • Ìgbà Òwúrọ̀
  • Ayaba Òòṣà
  • Àjànà orò
  • Fìjàbí
  • Ojú Ọ̀daràn Ré

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]