Àwọn èdè Adámáwá-Ubangi
Ìrísí
(Àtúnjúwe láti Àwọn èdè Adamawa-Ubangi)
| Adamawa-Ubangi | |
|---|---|
| (obsolete) | |
| Ìpínká ìyaoríilẹ̀: | West and Central Africa |
| Ìyàsọ́tọ̀: | Niger-Kóngò
|
| Àwọn ìpín-abẹ́: | |
Àwọn èdè Adamawa-Ubangi
Àkójopò àwon ède kan ni yí tí wón tó márùn-ún-dín-lógósàn-án (175). Wón wà ní apá àríwá ààrin gbùngbùn Aáfíríkà lati apá ìlà oòrùn nàìjíríà títí dé ìwò oòrùn Sùdáànù. Omo egbé Náíjá Kongò (Niger-Congo) ni wón. Wón n pè wón ni Ìla-oòrun Adamawá (Adamawa-Eastern) télè. Díè lára àwon èdè tó wà lábé ìpìn yìí ni Banda Gbanja àti Ngbika.
| Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |