Jump to content

Ọbánta

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Obanta
Awujale of Ijebu Kingdom

Reign 14th century
Born Ile Ife
Died Nigeria
Religion Yoruba

Ọbańta (tí orúkọ rẹ̀ gangan ń jẹ́Ogborogan) jẹ́ ọba aládé kẹta tí Ìjẹ̀bú, tí ó di Ìpínlẹ̀ Ogun lórílẹ̀ èdè Nigeria báyìí láti sẹ́ńtúrì kẹrìnlá .[1][2][3]

Ọbańta kó àwọn ènìyàn láti Ilé-Ifè wá sí Ìjẹ̀bú Òde níbi tí ó ti jọba lẹ́yìn tí bàbá ìyá rẹ̀, Ọba Olú Ìwà, Awùjalẹ̀ àkọ́kọ́ Ìjẹ̀bú Òde kú. Ní kété tí ó dé Ìjẹ̀bú Òde, àwọn ará ìbè gbáà tọwọ́tẹsẹ̀, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní kí í pé Ọba ìlú wà ní ìta. Èyí ni bí ọba Ogborogan ṣe ń jé Ọbańta.[4]

Àwọn ìrandíran Ọ̀bańta sì bẹ̀rẹ̀ sí ní joyè Awùjalẹ̀ tí Ìjẹ̀bú Òde, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn olóyè rẹ̀ máa ń dín agbára rẹ̀ kù. [5]

Titi di òní, ère rẹ̀ tí wọ́n fi bọlá fún un ṣì wà ní ìlú Ìjẹ̀bú Òde lẹ́bàá Itale.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Nigeria Magazine. Federal Ministry of Culture and Social Welfare. Government of Nigeria, Indiana University. 1965. p. 177. https://books.google.com/books?id=mRYOAQAAMAAJ. 
  2. Bernard I. Belasco (1980). The entrepreneur as culture hero: preadaptations in Nigerian economic development. Praeger(University of Michigan). p. 72. https://books.google.com/books?id=2PwNAQAAMAAJ. 
  3. Ifẹ̀: Annals of the Institute of Cultural Studies, University of Ife, Nigeria. Obafemi Awolowo University. Institute of Cultural Studies. 1986. https://books.google.com/books?id=QDE8AQAAIAAJ. 
  4. Robert Smith (1969). Kingdoms of the Yoruba. Methuen & Co. pp. 77–78. https://books.google.com/books?id=ric6OhxbCS0C&pg=PA77. 
  5. Robert Smith (1969). Kingdoms of the Yoruba. Methuen & Co. p. 79. https://books.google.com/books?id=ric6OhxbCS0C&pg=PA78.