Abayomi Oluyomi
Ìrísí
Abayomi Oluyomi je olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Naijiria lati ipinle Eko ni Naijiria . O ti gba iwe-ẹkọ Bachelor ati Master's ni Finance, Accounting, ati Banking lati University of Lagos . Ni odun 2023, won yan an gẹ́gẹ́ bi Komisana fun eto ìnáwó ni Ìpínlẹ̀ Eko. O tun ti ṣe awọn ipo iṣelu ati olori miiran, pẹlu sise bi Oludamoran Pàtàkì. [1] [2] [3]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2025-01-07. Retrieved 2025-01-07.
- ↑ https://finance.lagosstate.gov.ng/2023/09/15/mr-abayomi-oluyomi-honourable-commissioner/
- ↑ https://punchng.com/smes-critical-for-sustainable-development-lagos-commissioner/