Abdullahi Sule

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Engineer Abdullahi Sule
Gómìnà ìpínlẹ̀ Nasarawa
Bayaran Lafia
AsíwájúUmaru Tanko Al-Makura
DeputyDr Emmanuel Akabe
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíOṣù Kejìlá 26, 1959 (1959-12-26) (ọmọ ọdún 64)
Gudi Station, Akwanga, Nasarawa State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNàìjíríà
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress
(Àwọn) olólùfẹ́Hajiya Silifa, Hajiya Farida
Àwọn òbíAlhaji Sule(Father), Hajiya Hauwa Sule(Mother)
Alma materRoman Catholic Mission (1968), Zang Commercial Secondary School (1974), Government Technical College, Bukuru (1977), Plateau State Polytechnic (1980), Indiana University (1980–1984).
OccupationBusinessman, Engineer, Politician

Abdullahi Sule (a bi ni ọjọ kẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, Oṣu kejila, ọdun 1959) jẹ oniṣowo ati olóṣèlú Naijiria ti o jẹ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa. Wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa nínú ìdìbò Gómìnà ọdún 2019 lábẹ́ ètò ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC).[1][2][3]

Ìgbésí ayé rẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Sule ní Gudi, Akwanga ní ìpínlẹ̀ Nasarawa ní ọjọ́ kẹrindinlogbon oṣù Kejìlá ọdún 1959.[4] Ni ọdún 1968, Ó kẹ́kọ́ ní ilé-ẹ̀kọ́ Roman Catholic Mission (RMC) tí ó wà ní Gudi Station, ti o sí parí ilé-ẹ̀kọ́ gírámà ní Zang Secondary School ní ọdún 1974.[4]

Òṣèlú[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ni ọjọ kẹwà oṣù kẹta ọdún 2019, wón kede Adullahi Sule gẹgẹ bi gómìnà Ipínlè Nasarawa ti wón dibo yan.[5][6][2]

Àwọn itọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Muhammad, Ibraheem Hamza; Lafia (March 11, 2019). "INEC declares APC's Abdullahi Sule Governor-elect in Nasarawa". Daily Trust. Archived from the original on 23 March 2019. Retrieved 12 March 2019. 
  2. 2.0 2.1 "INEC declares Abdullahi Sule winner Nasarawa guber poll". The Sun Nigeria. March 11, 2019. Retrieved 12 March 2019. 
  3. "Govs not against direct primaries, says Gov Sule". Punch Newspapers. 2022-01-16. Retrieved 2022-03-06. 
  4. 4.0 4.1 "APC 's Abdullahi Sule to battle PDP's Ombugadu in Nasarawa". News Agency of Nigeria (NAN). October 1, 2018. Archived from the original on 2 October 2018. Retrieved 12 March 2019. 
  5. "Abdulahi Sule wins APC governorship primary in Nasarawa". The Express Tribune. October 1, 2018. Archived from the original on 2 October 2018. Retrieved 12 March 2019. 
  6. "INEC Declares Abdullahi Sule Winner of Nasarawa Governorship Race – Channels Television". Retrieved 12 March 2019.