Abiola Babes

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Abiola Babes jẹ́ ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá jẹun nígbà kan rí, ní ìlú Abẹ́òkúta lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Àgbà òṣèlú, olóògbé Bashorun Moshood K Abiola ní ó ni ín. Wọ́n gba ìgbéga sí ìdíje Àgbábuta Bọ́ọ̀lù Àfẹsẹ̀gbá tí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lọ́dún 1984.

Lodun 2000, àtúnṣe dé bá ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá náà, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ààlè lé wọn lọ́dún 2001 nítorí ìṣòro àìlówó. [1][2] Their last game was in the 2001 Challenge Cup against NIPOST FC.[3]

Àwọn Àṣeyọrí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Olùbórí nínú ìdíje ipele kejì lọ́dún 1983(Nigeria 2nd Division Champion

1983)

Akitiyan wọn nínú ìdíje CAF[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

1986: Wọn já kulẹ̀ lábala àkọ́kọ́
1987: Wọn pegedé sí aba tó ká gún sí àṣekág á (Semifinals)

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]