Ada Ehi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:Use mdy dates

Ada
Ada Ehi live in Douala, Cameroon, February 2020
Ada Ehi live in Douala, Cameroon, February 2020
Background information
Orúkọ àbísọAda Ogochukwu Ehi
Wọ́n tún mọ̀ọ́ bíiAda Ehi
Ọjọ́ìbí18 Oṣù Kẹ̀sán 1987 (1987-09-18) (ọmọ ọdún 36)
Irú orin
Occupation(s)Singer-songwriter, recording artist
InstrumentsVocals
Years active2009–present
Labels
Websiteadaehi.com

Ada Ogochukwu Ehi tí wọ́n bí lọ́jọ́ kejìdínlógún oṣù kẹsàn-án ọdún 1987 (18 September 1987), simply known by her stage name jẹ́ akọrin ajíyìnrere, oǹkọ̀wé orin àti Òṣèrébìnrin ọmọ Nàìjíríà.[1] Nígbà tí ó wà lọ́mọdún mẹ́wàá ló ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ̀ nígbà tí ó gbe orin fún akọrin ọmọdé ẹgbẹ́ rẹ̀, Tosin Jegede. Láti ìgbà tí ó ti ń korin lábẹ́ ilé orin, Loveworld Records lọ́dún 2009, ló ti di gbajúmọ̀ ìlúmọ̀ọ́ká olórin.[2][3]

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìgbésí ayé rẹ̀ àti àti ìgbéyàwó[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Ada sí idiley Victor àti Mabel Ndukauba, òun àti àwọn àbúrò rẹ̀ mẹta jọ dàgbà sí ìdílé ìgbàgbọ́ pẹ̀lú gbígbọ́ orin ìgbàgbọ́. Ó jẹ́ ọmọ Ìpínlẹ̀ Imo ní Nàìjíríà. [4] Nígbà tó wà lọ́mọ̀ ọdún mẹ́wàá, Wọ́n yàn án pọ̀ mọ́ àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin tí ó wà nínú ikọ̀ agberin fún gbajúmọ̀ ọmọdé olórin Tósìn Jẹ́gẹ́dẹ́.

Ó kàwé gboyè nínú ìmọ̀ ẹ̀rọ olóró (Chemical & Polymer Engineering) ní Lagos State University, ní àkókò náà, ó dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ ìsìn Believers Loveworld Campus Fellowship.[5]Lẹ́yìn náà, ó dára pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin Christy Embassy, tí ó sìn darapọ̀ mọ Loveworld Records lọ́dún 2009.[6]

Ó pàdé ọkọ rẹ̀, Moses Ehi, ní ìjọ Christ Embassy church nínú ẹgbẹ́ akọrin. Wọ́n fẹ́ ara wọn lọ́dún 2008,wọ́n sìn bímọ méjì fún ara wọn.[7][8][9]

Iṣẹ́ orin[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Láti ìgbà tí ó ti dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ akọrin ìjọ Christ Embassy, ó ti bá wọn kópa nínú oríṣiríṣi ètò káàkiri Nàìjíríà àti ní àwọn orílẹ̀-èdè àgbáyé .[10] Àwo orin rẹ̀ àkọ́kọ́ tí ó pè ní Undenied ló gbé jáde lọ́dún 2009, tí ó sìn gbé ìkejì jáde lọ́dún 2013 èyí tí ó pè ní Lifted & So Fly.[11][12][13][14] Àwo orin rẹ̀ ìkẹta tí ó pè ní Future Now, jáde lọ́dún 2017, ó sìn di orin gbajúmọ̀ àkọ́kọ́ ní ìkànnì iTunes Nigeria lọ́jọ́ tó jáde gangan.[15]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ada Ehi biography". UzomediaTV- YouTube. August 1, 2017. Retrieved July 10, 2017. 
  2. Jayne Augoye (July 8, 2017). "Gospel music singer, Ada Ehi, raises the bar with 'Overcame' video". Premiumtimes Nigeria. Retrieved July 10, 2017. 
  3. Daniel Anazia (July 8, 2017). "Ada reaches new height with Overcame". Guardian NG. Retrieved July 10, 2017. 
  4. "Ẹda pamosi". Archived from the original on September 20, 2022. Retrieved November 13, 2020. 
  5. Chinyere Abiaziem (July 17, 2017). "'You Do Not Have To Be Naked to Look Good' – Ada". Independent NG. Retrieved July 17, 2017. 
  6. https://www.busytape.com/ada-ehi-biography/
  7. https://africachurches.com/profile-and-biography-of-ada-ogochukwu-ehi/
  8. "Ẹda pamosi". Archived from the original on September 20, 2022. Retrieved November 13, 2020. 
  9. https://www.busytape.com/ada-ehi-biography/
  10. Uche Atuma (July 16, 2017). "WHAT I LEARNT FROM PASTOR CHRIS OYAKHILOME – Ada Ehi, International Gospel Music Minister". Sunnewsonline. Retrieved July 20, 2017. 
  11. Francisca Kadiri (February 26, 2016). "Ada Ehi". Online Nigeria. Retrieved July 10, 2017. 
  12. ThisDay (August 29, 2009). "Nigeria: The Emergence of Love World Records". channelstv. Retrieved July 21, 2017. 
  13. nigeriatribune (June 11, 2017). "My music saved a woman from suicide —Ada Ehi". Nigeriatribune. Retrieved July 10, 2017. 
  14. Alex Amos (August 31, 2013). "UPCLOSE: "I ROAR IN TONGUES" – "I’M RICH" CROONER ADA EHI IS ON FIRE! TALKS SPIRITUALITY, UPCOMING ALBUM, LOVE, FASHION AND MORE". selahafrik. Retrieved July 10, 2017. 
  15. "Ada's New Album "Future Now" races to No. 1 Spot on iTunes Nigeria Same Day of Release – BellaNaija". BellaNaija. Retrieved October 25, 2017.