Adalu (ounje)
Adalu jẹ ounje kan ti á màn pe ni Asáró ni orilẹ-ede Naijiria ti a hún fí agbado ati ẹwa sè, o de gbajumo laarin awọn Yoruba ati awọn Igbo.
Igbaradi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
A o se agbado ati ewa lọtọ ki a to da awon mejéjì pápọ . [1] A ó sí fi epo púpa, alubosa, ata ati iyọ si ko le ba dun.
A má n jé Adalu pelú ogede ati eja sisun.
Wo awon eleyi na[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- Ounje ni ilu Naijiria
- agbado didun
- Ewa aganyin, ounje Naijiria miiran ti a hún fí ewa se.
Awọn itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ https://guardian.ng/life/how-to-make-adalu-beans-and-corn/