Adebimpe Oyebade
Ìrísí
| Adebimpe Oyebade | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 23 Oṣù Kẹta 1992 |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Orúkọ míràn | Mo Bimpe[1] |
| Ọmọ orílẹ̀-èdè | Nigeria |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Ekiti State University |
| Iṣẹ́ | Film actress |
| Olólùfẹ́ | |
Adebimpe Oyebade (tí a bí ní 23 oṣù kẹta 1992) tí a mọ̀ sí Mo Bimpe jẹ́ òṣèré fíìmù Nàìjíríà tí a mọ̀ fún gbígba àmì-ẹ̀yẹ ti ọdún 2018 ní City People Entertainment Awards gẹ́gẹ́ bíi òṣèré titun titun ti ọdún náà.
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Bassey, Ekaete (July 14, 2022). "Why Fabiyi and I are ‘enemies’ – Mo Bimpe The Nation Newspaper". The Nation Newspaper. Retrieved July 22, 2022.