Adebola Williams

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Adebola Williams
Ọjọ́ ìbí7 Oṣù Kẹta 1986 (1986-03-07) (ọmọ ọdún 38)
Nigeria
Iṣẹ́Journalist/media entrepreneur
Alma materLondon School of Journalism, Pan African University
Notable awardsMandela Washington Fellow;[1] 100 Most Influential People of African Descent under the United Nations International Decade for People of African Descent;[2] Archbishop Desmond Tutu Fellowship in South Africa[3]

Adebola Williams ( Abíi ní ọdún 1986) ó jẹ́ ọmọ orile-èdè Nigeria tí ó ń ṣe òwò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, akọ̀ròyìn, olùgbaninímọ̀ràn nípa ọ̀rọ̀ òṣèlú, àti olùsọ̀rọ̀-ìwúrí. Òun ni Olùdarí-àgbà fún ẹgbẹ́ RED | For Africa. Ó jẹ́ olùjọdásílẹ̀ àti alámòjútó Red Africa,  Ilé iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ tí ó ṣe agbátẹrù àwon ọ̀dó jùlọ ní ilẹ̀ Africa ní àjọṣe pẹ̀lú Red Media Africa, Statecraft Inc., The Future Awards Africa, and YNaija.[4]


Adebola Williams ( Abíi ní ọdún 1986) ó jẹ́ ọmọ orile-èdè Nigeria tí ó ń ṣe òwò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, akọ̀ròyìn, olùgbaninímọ̀ràn nípa ọ̀rọ̀ òṣèlú, àti olùsọ̀rọ̀-ìwúrí. Òun ni Olùdarí-àgbà fún ẹgbẹ́ RED | For Africa.[5] Ó jẹ́ olùjọdásílẹ̀ àti alámòjútó Red Africa,  Ilé iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ tí ó ṣe agbátẹrù àwon ọ̀dó jùlọ ní ilẹ̀ Africa ní àjọṣe pẹ̀lú Red Media Africa, Statecraft Inc., The Future Awards Africa, and YNaija.[6]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Matilda Kerry, Adebola Williams, Otto Orondaam & other outstanding Young Nigerians selected for 2016 Mandela Washington Fellowship". BellaNaija. Retrieved 6 May 2016. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  2. "Most Influential People of African Descent (MIPAD) unveils 2017 Global List". mipad.org. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  3. "Tutu Fellows". alinstitute.org. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  4. "Adebola Williams". World Economic Forum (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-03-18. 
  5. "Interview: Meet The 30 Year-Old Nigerian Entrepreneur Who Helped 3 African Presidents Get Elected". Forbes. 17 February 2017. https://www.forbes.com/sites/mfonobongnsehe/2017/02/17/meet-the-30-year-old-nigerian-entrepreneur-who-helped-3-african-presidents-get-elected/. 
  6. "The Young Moguls that built a Media Empire in Nigeria with zero capital". Tech Point. 31 October 2016. https://techpoint.ng/2016/10/31/red-media-founders-interview/.