Jump to content

Aláàfin Olúewu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Oluewu jẹ́ Alaafin tó lágbára gan-an ní ìlú Ọ̀yọ́ tí ó ń pàṣẹ Oyo empire lápá òkè oya ilẹ̀ Yorùbá ní Nigeria láti ọdún 1833 sí 1835.[1]

Aláàfin Olúewu ni ó yẹ kí o jọba Ìlọrin lẹ́yìn Ṣítà, ṣùgbọ́n ó kọ̀ jálẹ̀ láti ṣe ẹ̀sìn Mùsùlùmí, bẹ́ẹ̀ ló lọ wá ìrànlọ́wọ́ àwọn Borgu láti borí ogun àwọn Fulani. Ní ìbẹ̀rẹ̀, ó gbìyànjú ṣùgbọ́n igbiyanju rẹ̀ nígbẹ̀yìn láti gba àwọn ìran Yorùbá tí wọ́n wà lókè oya padà jásí ikú fún un láti ọwọ́ Okèdáre Lánlókè àti àwọn èèyàn pàtàkì kan láti Ọ̀yọ́.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]