Jump to content

Al-Wafa bi Asma al-Nisa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Al-Wafa bi Asma al-Nisa
Fáìlì:Cover of Al-Wafa bi Asma al-Nisa.jpg
Arabic cover
Olùkọ̀wéAkram Nadwi
CountryUnited Kingdom
LanguageArabic
SubjectHadith studies
GenreBiography
PublisherDar al-Minhaj
Publication date
2021
ISBNÀdàkọ:ISBNT
OCLC1252541014
920.71
Websitealsalam.ac.uk
An introductory note in English for the book Al-Muhaddithat, released in 2007

Al-Wafa bi Asma al-Nisa ( Arabic </link> ni ìwé òdodo tí ó kún fún àwọn orúkọ Obìnrin) ó jẹ́ ìwé tí ó ní ìwọn ẹ̀tà-lẹ́-lógójì tí ó dá lóri ìgbésí ayé àwọn Lárúbáwá tí wọ́n jẹ́ obìnrin tí wọ́n jẹ́ olùkópa nínú àlàyé tí àwọn Àdíìsì tàbí kó ipa ribiribi nínu ìfiléde.

Iṣẹ́ náà jẹ́ àwọn ìpele ìwọ̀n mẹ́tà-lé-lógójì. Iwọn akọkọ ṣe àfihàn àwọn àlàyé tí àwọn Àdíìsì tí wọ́n dárí sọ àwọn obìnrin tí wọ́n jẹ́ olùkópa, nígbà tí ìwọn ẹlẹ́ẹ̀kejì ṣé àgbéyẹ̀wò àwọn obìnrin ilé ẹ Ànábì. Àwọn ìpele tí ó tẹ̀lé e ṣe àlàyé àwọn ẹlégbè obìnrin (3–10), Tabi’un (11–13) àti àwọn òpìtàn-onímọ̀ (14–42) ní àsọtẹ́lẹ̀ ní bíi àwọn ọgọ́rùn-ún ọdún. Ìwọn 43 yí padà sí orí àwọn òpìtàn-onímọ̀ òde òní, pẹ̀lú díẹ̀ nínú àwọn tí wọ́n tún ṣiṣẹ́ lọ́wọ́ . [1] Ìwé náà gbé ìtàn àkọ́lé òtító tàbí a bójú-ayé-mú gorí í ìtúpalẹ̀, àwọn ìgbìyànjú láti mú ìwòye àgbáyé nípa fífi Àdíìsì àwọn obìnrin tí wọ́n jẹ́ òpìtàn-onímọ̀ hadith obinrin tí wọ́n wà ní ìkọjá a Àárín-in Ìlà-Oòrùn. Àwọn títẹ síi ìtàn-ayé yàtọ̀ ni ìjìnlẹ̀, pẹ̀lú àkọyawọ́ tí ó léni ojú ìwé igba ti o tẹpẹlẹ mọ́ àtúnṣe sí iṣẹ́ àwọn yòókù, ní kúkúrú nípa àwọn òpìtàn-onímọ̀ ọkùnrin. Wọ́n ṣe àwọn àkójọpọ̀ yìí látara àwọn ìpamọ́ bíi ìwé ìforúkọsílẹ̀ ní yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ àti ijazahs, ní èyí tí ó ṣe àfihàn bí àwọn obìnrin ṣe gbé àṣẹ lé àwọn ọkùnrin lọ́wọ́ láti má a kọ́ni. Ó tún lo ìtọ́ka láti ọ̀dọ 'ulema tí ó ṣe wí pé o

Ní ọdún-un 1989, Akram Nadwi kó ipa ti Ẹlẹgbẹ́ Ìwádìí kan ní Ilé-ẹ̀kọ́ gíga Oxford ti Oxford Centre fún Islamic Studies, ní èsì sí ìdá ìbéèrè láti ọ̀dọ Abul Hasan Ali Hasani Nadwi. Nígbà ìṣàkóso rẹ̀, ó ṣe àbápàdé àwọn àkọ́lé kan nínú ìwé ìròyìn "Time'' tí wọ́n ṣe àtẹ̀jáde wí pé wọ́n ń ṣe ìdènà fún obìnrin nínú ẹ̀kọ́ ọ wọn, wí pé obìnrin ò ní ipa tí wọ́n ń kó nínú ẹ̀kọ́ àti ìmọ̀ tí ó dá lóri iṣẹ́ ìwádìí nínú Islam.

Dhaka Post ṣe àfihàn pàtàkì ti iṣẹ́ yìí ní sísọ ìtàn ọgbọn-ọ-gbọ́n Islam ti ọ̀rúndún 21st, tí ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi itọkasí àti ìwífún tí ó lágbára lòdì sí àwọn àìṣe-déédé Islam, pàápàá ní sísọ àwọn ẹ̀sùn èké tí ó ní ìbátan sí ìlọsíwájú àti ẹ̀kọ́ àwọn obìnrin. [2] Majalla yin iṣẹ́ yìí gẹ́gẹ́ bí ìwé ìmọ̀ àgbọ́n-ọ̀n-gbẹn tí wọ́n fi sọrí àwọn obìnrin tí wọ́n lààmì-laaka tí wọ́n sì tún jẹ́ onísọ̀rọ̀ Àdíìsì . [3]

Àwọn ìtọ́ka sí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Empty citation (help) 
  2. Minhaj Uddin, Muhammad (14 January 2021). "Exploring the Contributions of Muslim Women Scholars: A 43-Volume Compilation" (in bn). Dhaka Post. Archived on 27 July 2021. Error: If you specify |archivedate=, you must also specify |archiveurl=. https://www.dhakapost.com/amp/religion/5338. 
  3. Al-rashid, Abdullah (17 October 2023). "The 'unknown' Arab and Muslim women scholars, who taught some of history's most esteemed men". The Majalla. Archived on 20 November 2023. Error: If you specify |archivedate=, you must also specify |archiveurl=. https://en.majalla.com/node/300871/culture-social-affairs/unknown-arab-and-muslim-women-scholars-who-taught-some-historys.