Alimi Adewale

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Alimi Adewale (tí a bí ní May 8, 1974)ó jẹ olóṣèré wíwò àti olùyàwòrán ní àwùjọ àwọn ènìyàn ní orílẹ èdè Naijiria . [1] [2] Ṣùgbọ́n ìfẹ́ rẹ̀ sí iṣẹ́ ọnà àti àwọn ìfihàn ṣe ìwúrí ìfẹ́ rẹ̀ láti di òlóṣèré. Àwọn iṣẹ́ rẹ̀ máa ń sábà dálé àárín ìlú, ìṣàwárí rẹ̀ pèlú, gbogbo ìgbekalẹ̀ rẹ̀ tí àwọn ará ìlú ojoojúmọ́, àti àwọn kókó ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì í máa ń jẹ́ àríyànjiyàn ti 'Nudes in African Art' gẹ́gẹ́ bí ìrísí ìkọsílẹ̀ rẹ̀. [3]

Wo eléyìí náà[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Empty citation (help) 
  2. Empty citation (help) 
  3. Empty citation (help)