Angelica Nwandu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Angelica Nwandu
Nwandu in 2020
Ọjọ́ìbíOṣù Kàrún 10, 1990 (1990-05-10) (ọmọ ọdún 33)
Los Angeles, California
Iṣẹ́Online Black celebrity gossip
Ìgbà iṣẹ́2014-present
Gbajúmọ̀ fúnFounder, the Shade Room

Angelica Nwandu (tí wọ́n bí ní May 10, 1990)[1][2] ni olùdásílẹ̀ the Shade Room (TSR), èyí tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára tó níṣe pẹ̀lú ṣíṣe òfófó àwọn gbajúmọ̀. Iye àwọn ènìyàn tó ń wo ètò yìí ń lọ bí i 20 million.[3][4] Ní ọdún 2016,The New York Times to the Shade Room sábẹ́ àwọn ètò tó gbajúmọl jù lọ ní orí ẹ̀rọ-ayélujára.[5]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Abumere, Princess (May 10, 2017). "5 things you should know about the Shade Room founder". pulse.ng. Retrieved June 4, 2020.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "Today is my bday". www.instagram.com. Retrieved 2023-07-22. 
  3. "Live Session With Angelica Nwandu CEO and Founder of The Shade Room". The Hype Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-16. 
  4. Davis, Allison P. (2019-10-21). "How I Get It Done: Angelica Nwandu, Founder and CEO of The Shade Room". The Cut (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-07-22. 
  5. Wortham, Jenna (April 14, 2015). "Instagram's TMZ". The New York Times.