Anthonia Adenike Adeniji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Anthonia Adenike Adeniji
BornOṣù Kẹ̀sán 25, 1971 (1971-09-25) (ọmọ ọdún 52)
Ota, Ogun, Nàìjíríà
InstitutionsYunifásítì ti Covenant
Alma materOlabisi Onabanjo University (B.Sc.)
Obafemi Awolowo University (M.B.A.)
Covenant University (Ph.D.)

Anthonia Adenike Adeniji (tí a bí ní ọjọ́ karúndínlọ́gbọ̀n oṣù keje ọdún 1971) jẹ́ ọ̀mọ̀wé àti ọ̀jọ̀gbọ́n ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ igbákejì ọ̀jọ̀gbọ́n[1] nínú ìmò dídarí ọkọ òwò ní Yunifásítì Covenant, Ìpínlẹ̀ Ogun, Nàìjíríà.

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Adeniji ní ọjọ́ karúndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 1971, ní Ìlú Ota, ti ìpínlẹ̀ Ogun State. Ó parí ẹ̀kọ́ B.Sc. rẹ̀ nínú ìmọ̀ ìdarí ọkọ òwò ní ọdún 1995 ní Yunifásítì Olabisi Onabanjo. Ó gba àmì-ẹ̀yẹ Post Graduate Diploma in Financial Management (PGDFM) ní ọdún 1997 ní Yunifásítì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ níbè ló tún ti gba àmì-ẹ̀yẹ M.B.A. ní ọdún 2000 kí ó tó gba àmì-ẹ̀yẹ P.H.D. ní Yunifásitì Covenant ní ọdún 2011.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Dr. Anthonia Adenike Adeniji". Covenant University. Archived from the original on 24 November 2020. Retrieved 29 May 2020.