Audrey Ajose

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Omoba
Audrey Olatokunbo Ajose
Ọjọ́ìbí1937
Iṣẹ́
  • Lawyer
  • writer
Parent(s)
  • Omoba Oladele Ajose
  • Beatrice Spencer Roberts

Audrey Olatokunbo Ajose (ọjọ́-ìbí c. 1937) jẹ́ Àgbẹjọ́rò àti Akòwé ọmọ Nàìjíríà. Ó ṣiṣẹ́ bí aṣojú orílẹ̀-èdè rẹ̀ sí Scandinavia láti ọdún 1987 sí 1991. [1]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ Ayé Rẹ̀ Àti Ẹ̀kọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọmọbìnrin Ọmọba Oladele Ajose àti Beatrice Spencer Roberts.[2] Audrey Ajose jẹ́ ọmọ obìnrin ilẹ̀ òkèèrè kan tí ó fẹ́ ọmọ Nàìjíríà. [3] Ó kọ ẹ̀kọ́ ìròyìn ní Regent Polytechnic. Ọ́ kọ ẹ̀kọ́ àti àdaṣe òfin ṣùgbọ́n tún tẹ̀síwájú láti ṣiṣẹ́ ní ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́. [4] Ó tún kọ ẹ̀kọ́ nípa'theology' [5] [6]ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ nípa 'theology' ní ilé ìjọsìn Lutheran.

Àwọn Iṣẹ́ Tí A Yàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Yomi's Adventures, juvenile fiction (1964)[7]
  • Yomi in Paris, juvenile fiction (1966)

[1]

Àwọn Ìtọ́ka Sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "Ajose, Audrey (Nigeria)". Literary Map of Africa. Ohio State University. 
  2. "Tribute to Late Oladele Adebayo Ajose". The Sun (Nigeria). July 17, 2003. http://news.biafranigeriaworld.com/archive/2003/jul/17/0074.html. 
  3. "Foreign women married Nigerians, nigerwives, foreign women in nigeria". nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-27. 
  4. "Audrey Ajose | Academic Influence". academicinfluence.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-27. 
  5. "AUDREY AJOSE: How I dared soldiers who held us captive in newsroom during 1985 coup - The Nation Newspaper" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-12-11. Retrieved 2022-05-27. 
  6. "MFR Audrey Olatokunbo Ajose". Government College Ibadan Old Boy's Association. Archived from the original on 2023-04-26. Retrieved 2023-04-26. 
  7. "National Academic Digital Library of Ethiopia". ndl.ethernet.edu.et. Retrieved 2022-05-27.