Bolanle Ninalowo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Bọ́láńlé Nínálowó)
Bolanle Ninalowo
Bolanle Ninalowo at the 2020 AMVCA
Ọjọ́ìbí7 Oṣù Kàrún 1980 (1980-05-07) (ọmọ ọdún 43)
Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànNino
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaDeVry University
Iṣẹ́Actor
Ìgbà iṣẹ́2010–present

Bọ́láńlé Nínálowó tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ní ó (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ keje oṣù karùn-ún ọdún 1980) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré sinimá àgbéléwò àti onímọ̀ Ìsirò-owó ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ṣùgbọ́n tí ó ń gbé ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà. Bí ó ṣe ń ṣeré tíátà, bẹ́ẹ̀ náà ló jẹ́ akọrin. [1][2][3]

Ìgbà èwe àti aáyan ìkẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Nínálowó sí ìlú Ìkòròdú ni ìpínlẹ̀ Èkó lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Kí óó dèrò ìlú-ọba ó kàwé àkóbẹ̀rẹ̀ àti sẹ̀kọ̀ndìrì rẹ̀ ní ìlú Èkó.[4]

Ìgbìyànjú nídìí ìṣe sinimá àgbéléwò[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Gẹ́gẹ́ bí a ṣe sọ síwájú, Nínálowó jẹ́ onímọ̀ Ìsirò-owó, nítorí ìdí èyí, ó kọ́kọ́ ṣíṣe ni ilé-ìfowópamọ́ gẹ́gẹ́ bí Aṣèṣirò-owó (Accountant) fún ìgbà díẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà kí ó tó dára pọ̀ mọ́ ìṣe eré sinimá àgbéléwò ṣíṣe lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bákan náà, nígbà tí ó padà sí Nàìjíríà, ó tún bá ilé-ìfowópamọ́ Guaranty Trust Bank ṣíṣe kí ó tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà. Nínálowó kò fi bẹ́ẹ̀ rọ́wọ́ mú nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ sinimá àgbéléwò gẹ́gẹ́ bí olóòtú, ṣùgbọ́n lọ́dún 2014, ní ó ṣẹ̀ṣẹ̀ wá di gbajúmọ̀ nídìí ìṣe sinimá àgbéléwò.[5] [6]

Àwọn àmìn ẹ̀yẹ tí ó ti gbà àti àwọn tí wọ́n dárúkọ díje rẹ̀ fún[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Revelation of the Year, Best of Nollywood Award, 2010
  • Best Supporting Actor of the Year ‘English’, City People Movie Award, 2017[7]
  • The Best Actor in a Leading Role ‘English‘ Picture Perfect’ Best of Nollywood Awards (BON), 2017
  • Best Actor of the Year ‘English’ City People Movie Award, 2018
  • Best Actor of the Year ‘English’, City People Movie Award, 2018


Àtòjọ díẹ̀ nínú àwọn sinimá-àgbéléwò tí ó ti kópa[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]


Awon àmì ẹ̀yẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Year Award ceremony Prize Result Ref
2010 Best of Nollywood Awards Revelation of the Year Gbàá
2017 City People Movie Award Best Supporting Actor of the Year - English Gbàá [8]
Best of Nollywood Awards Best Actor in a Lead role - English Gbàá [9]
2018 Best of Nollywood Awards Best Actor in a Lead Role - Yoruba Wọ́n pèé
City People Movie Award Best Actor of the Year - English Gbàá

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Why my marriage failed –Bolanle Ninalowo". Newtelegraph. 2017-12-31. Archived from the original on 2019-12-21. Retrieved 2019-12-17. 
  2. Nigeria, Information (2018-03-21). "My success story in Nollywood – Bolanle Ninalowo". Information Nigeria. Retrieved 2019-12-17. 
  3. Bada, Gbenga (2015-05-13). "Rukky Sanda’s cousin becomes Nollywood’s new toast". Pulse Nigeria. Retrieved 2019-12-17. 
  4. "Bolanle Ninalowo biography, net worth, age, family, contact & picture". Nigeria Business Directory - Find Companies, People & Places in Nigeria. 1980-05-07. Retrieved 2019-12-17. 
  5. "Bolanle Ninalowo Biography & Net Worth". 360dopes. 2018-07-20. Retrieved 2019-12-17. 
  6. "BOLANLE NINALOWO: WHY I SEPARATED FROM THE MOTHER OF MY KIDS - The Nation Newspaper". The Nation Newspaper (in Èdè Latini). 2017-11-03. Retrieved 2019-12-17. 
  7. Emmanuel, Daniji (2017-10-18). "Full List Of Winners At The 2017 City People Movie Awards". City People Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2019-11-23. 
  8. Emmanuel, Daniji (18 October 2017). "Full List Of Winners At The 2017 City People Movie Awards". City People Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 23 November 2019. 
  9. "BON Awards 2017: Kannywood’s Ali Nuhu receives Special Recognition Award". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 23 November 2017. Retrieved 7 October 2021.