Bella Disu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Bella Disu
Ọjọ́ìbíBelinda Ajoke Olubunmi Adenuga
29 Oṣù Kàrún 1986 (1986-05-29) (ọmọ ọdún 37)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́
Iṣẹ́Business Executive
Ìgbà iṣẹ́2004–present
Olólùfẹ́Jameel Disu
Parent(s)
Websitebella-disu.com

Belinda "Bella" Ajoke Olubunmi Disu (orúkọ baba rẹ̀ ni Adenuga, wọ́n bí ní 29 May 1986) jé obinrin onísòwò omo Nàìjirià [1]. Òun ni alaga Abumet TNigeria Limited, [2], ígbákejì Alaga ilé ise Globacom, [3], oun sì tún ni oga agba cobble stone property and estate limited ati alaga Julius Berger Nigeria plc [4]

Àárò ayé àti èkó rè[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Bella Disu ní 29 may, 1986 sí inú idile Mike Adenuga(alaga Globacom) àti Emelia Adefolake, [5] okawe ní ìlú eko. Ilé ìwé akobere rè ní ilé-ìwé Corona, Victoria Highland, ósì lo ilé-ìwé Queen's College fún èkó Sekondiri rè. Ní odun 1998, ófi ilé-ìwé Queen's College kale láti lo si ilé-ìwé Vivian Fowler memorian College for girls, nibi tí o ti pari ìwé sekondiri ní odun 2000 [6].

Ogba àmì-èye Bachelor degree ní sayensi oselu àti International relations ní yunifásitì ti Massachusetts(ìlú Amerika), ósì tún gba àmì-èye M.sc ninú leadership ní yunifásitì ti Northeastern, Boston [7][8]

Isé rè[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní odun 2004, Bella darapò mó ilé ise Globacom Ltd, ósì ti di ara àwon oludari ilé isé náà. Ní odun 2011, o di òkan ninú àwon egbe oludari Cobblesrone estate and property Ltd, ósì di ògá àgbà ilé isé náà ní odun 2015. Ó tún jé oludari fún ilé isé Julius Berger tí èka Nàìjíríà. [9] [10] àti oludari Abamet plc, ilé isé tí óún se gilasi àti aluminum ní Nàìjíríà. Ní osù kiní odun 2019, ó di ígbákejì alaga ilé isé Globacom [11]

Ìdílé rè[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní osù kerin odun 2010, Bella fé Jameel Disu, wón sì bí omo méjì [12]

Àmì èye[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní December 2019, ìjoba French fún Bella ní àmì èye Ordre des Arts et des Lettres fún ìkópa ré nínú itoju art àti asa papajulo imojuto construction of the Alliance Francaise Mike Adenuga Centre, Ikoyi tí Eko [13]

Àwon ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Women in Business: Bella Disu". Businessday NG. 2019-08-09. Retrieved 2022-03-31. 
  2. Adeniyi, Olusegun (2021-01-26). "Abumet Nigeria Appoints Belinda Ajoke Disu Chairman". THISDAYLIVE. Retrieved 2022-03-31. 
  3. "Are you a robot?". Bloomberg. Retrieved 2022-03-31. 
  4. "Bella DISU". The AFRICA CEO FORUM (in Èdè Faransé). 2021-06-17. Retrieved 2022-03-31. 
  5. Akinwale, Funsho (2019-03-09). "Bella Adenuga Disu, others bag IoD certification". The Guardian Nigeria News. Retrieved 2022-03-31. 
  6. Olanrewaju, Sulaimon (2019-04-12). "Bella Disu: The Midas at Globacom". Tribune Online. Retrieved 2022-04-01. 
  7. Uriri, Francesca (2019-03-16). "Leading Ladies Africa Nigeria’s 100 most inspiring women in 2019". Guardian Woman. Retrieved 2022-04-01. 
  8. THISDAYLIVE, Home - (2018-10-07). "– A Daughter in a Million: The Amazing Exploits of Belinda Disu in BusinesTHISDAYLIVE". THISDAYLIVE. Retrieved 2022-04-01. 
  9. Ojekunle, Aderemi (2018-07-20). "Meet the daughters of 6 Nigerian billionaires and what they do". Business Insider Africa. Retrieved 2022-04-01. 
  10. "Globacom’s EVC, Bella Disu, Joins Others for Institute of Directors Certification". Nigerian CommunicationWeek. 2019-03-05. Retrieved 2022-04-01. 
  11. "Adenuga’s Daughter Assumes Number 2 Role At Globacom". Technology Times. 2019-01-30. Retrieved 2022-04-01. 
  12. "Classics: Inside Bella Adenuga, Jameel Disu's Engagement". Encomium Magazine. 2010-04-10. Retrieved 2022-04-01. 
  13. Omotayo, Joseph (2019-12-18). "Jubilation as Mike Adenuga’s daughter bags French prestigious national honour". Legit.ng - Nigeria news. Retrieved 2022-04-01.