Bilal Ibn Rabah

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Àyọkà yìí jẹ mọ́ nípa the companion of Muhammad. Fún the Mosque named in his honour, ẹ wo: Rachel's tomb.
Bilāl ibn Rabāḥ
بِلَال بِن رَبَاح
Born580 CE
BirthplaceMecca, Hejaz
Known forbeing the first mu'azzin in Islam history [1][2]
OccupationMuezzin and Secretary of Treasure of The Islamic State of Medina
TitleSayyid al-Muʾaḏḏin
DiedMarch 2, 640(640-03-02) (ọmọ ọdún 59–60) CE
FatherRabah
MotherHamamah
Wife
  • Hind
  • Hala bint Awf[3]
ReligionIslam

Bilāl ibn Rabāḥ (Lárúbáwá: بِلَال بِن رَبَاح‎), c. 580–640, jẹ́ ọ̀kan lára sàhabé tí Ànọ́bì Muhammad (S.W.T) gbẹ́kẹ̀le tí ó sí fọkàntàn tí Ànọ́bi náà sì jẹ́ ọ̀kan lára òjíṣẹ́ tí Ọlọ́run ran sí àwọn mùsùlùmí. Wọ́n bi sí Ìlu Mecca, tí wọ́n ṣì gbà ọ òun nì Mu'azzin àkọ́kọ́ nínú ìtàn, tíó jẹ́ pé ànọ́bí gan-an fúnrarẹ̀ ni ó yàn.[1][4][5][6] Ó jẹ́ ẹrú kan tẹ́lẹ̀rí tí ó wá láti Orílé èdè Ethiopia, tí ó sì jẹ́ olókìkí látàrí òhun dídùn tí ó ní tí ó sì fí ń pè àwọn ẹrùsìn ọlọ́run láti wà kí Ìrun. Ó jáde láyé ní Odún 640, tí ó sì wà ní ọmọ ọgọ́ta ọdún.

Bilal (left) with another of Muhammad's companions in Musa va 'Uj, an early 15th century painting
Bilal (left) with another of Muhammad's companions in Musa va 'Uj, an early 15th century painting

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "Slavery in Islam." BBC News. BBC, 2009. Web. 2013.
  2. Riz̤vī, Sayyid Sa'eed Ak̲h̲tar. Slavery: From Islamic & Christian Perspectives. Richmond, British Columbia: Vancouver Islamic Educational Foundation, 1988. Print. ISBN 0-920675-07-7 Pg. 35-36
  3. "الإصابة في تمييز الصحابة، لابن حجر العسقلاني، ترجمة هالة بنت عوف الزهرية، موقع صحابة رسولنا". Archived from the original on 2018-07-15. Retrieved 2021-05-30.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  4. Ludwig W. Adamec (2009), Historical Dictionary of Islam, p.68. Scarecrow Press. ISBN 0810861615.
  5. Robinson, David. Muslim Societies in African History. Cambridge, UK: Cambridge University Press, 2004. Print.
  6. Levtzion, Nehemia, and Randall Lee Pouwels. The History of Islam in Africa. South Africa: Ohio UP, 2000. Print.