Biola Adebayo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Biola Adebayo
Ọjọ́ìbí23 December
Ìpínlẹ̀ Èkó
Orílẹ̀-èdèNàìjíríà
Ọmọ orílẹ̀-èdè Nigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaYunifásitì ìlú Eko
Iṣẹ́Nollywood actress, Producer, TV Presenter
Ìgbà iṣẹ́2002 - Present
Olólùfẹ́Oluseyi

Biola AdebayoYo-Biola Adebayo.ogg gbọ́ jẹ́ òṣèrébìnrin tí ó ṣeré nínú àwọn eré bi Jade's cross, Tori Owo àti àwọn eré mìíràn.[1] Òṣèrébìnrin náà, Eniola Badmus àti Banky W ṣe ìpòlongo nípa àwọn ọ̀nà láti kọjú ààrùn coronavirus nípa tí ààrùn náà ń jà fitafita ní Nàìjíríà, wọ́n rọ àwọn ènìyàn láti dúró sínú ilé àti láti lọ àwọn èlò ìfowọ́.[2]

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Biola gba àmì-ẹ̀yẹ Master degree nínú ìmọ̀ Public Administration ní Yunifásítì ìlú Èkó.[3][4]

Àtòjọ àwọn fíìmù tí ó ti ṣeré[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Online, Tribune (2021-04-16). "Blingz Awards has become most anticipated in Ibadan — Convener". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-08-06. 
  2. "Coronavirus: Banky W, Eniola Badmus, Biola Adebayo urge calm". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-03-01. Retrieved 2022-08-06. 
  3. "Nollywood Actress Biola Adebayo bags new award - P.M. News" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-08-06. 
  4. Online, Tribune (2021-07-10). "Nollywood stars, Biola Adebayo, Mofe Jebutu, bag Master’s degrees". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-08-06. 
  5. "Rotimi Salami, Peju Ogunmola others reunite in 'Tori Owo'". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-03-27. Retrieved 2022-08-06.