Daisy W. Okocha

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Daisy W. Okocha
Adájọ́ àgbà keje ti ìpínlè Rivers
In office
4 January 2016 – 15 January 2016
Appointed byEzenwo Wike
AsíwájúIche Ndu
Arọ́pòAdama Lamikanra
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí15 Oṣù Kínní 1951 (1951-01-15) (ọmọ ọdún 73)
Obio Akpor, Rivers State
ProfessionLawyer

Daisy Wotube Okocha (tí a bí ní ọjọ́ keedogun oṣù kínní ọdun 1951) jẹ́ Adájọ́ àgbà ìpínlè Rivers, òun ni ó ní ìkáwọ́ High Court of Justice, àti Judicial Service Commission.[1] Gọ́minà Ezenwo Wike ni ó yàn sípò náà ní ọjọ́ kẹrin oṣù kínní ọdun 2016,[2] ó sì di ipò náà mú títí di ìgbà tí ó fi ipò náà kalẹ̀ ní ọjọ́ meedogun oṣù kínní ọdun 2016.[3]

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bi Okocha ní ìlú Obio-Akpor, Ìpínlẹ̀ Rivers, Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. ní ọjọ́ keedógún oṣù kínní, Ó jẹ́ ẹ̀yà Ikwerre. Bàbá rẹ̀, Jonathan Okocha, jẹ́ Kọmíṣọ́nà Ọlọ́pá tẹ́lẹ̀ rí, ìyá rẹ̀, Helen Nonyelum Okocha sì ń ta oúnjẹ.[4]

Daisy gba àmì-ẹ̀yẹ ti ìmọ̀ òfin LL.B. (Hons.) ní Yunifásítì Àmọ́dù Béllò ní ọdun 1978. Ní ọdun tí ó tẹ́lẹ̀, ní ọjọ́ kàndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹfà, wọ́n gba sínú isẹ́ ìmò òfin.

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Chioma, Unini (2016-01-05). "Rivers gets first female chief judge". TheNigeriaLawyer (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-28. 
  2. Ihunwo, Tony (2016-01-04). "Governor Wike Swears In First Female Chief Judge In Rivers State, What She Said (PHOTOS)". Legit.ng - Nigeria news. (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-28. 
  3. Amadi, Akujobi. "As Justice Okocha Bids Rivers Judiciary Farewell" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-28. 
  4. Chioma, Unini (2016-01-05). "Rivers gets first female chief judge". TheNigeriaLawyer (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-28.