Dapo Olorunyomi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Dapo Olorunyomi
Page Module:Infobox/styles.css has no content.
Publisher of Premium Times newspaper
In office

June 2011 – To date
Personal details
Born
Oladapo Oyekunle Olorunyomi


(1957-11-08) 8 November 1957 (age 65)

Kano, Kano State, Nigeria
Profession Journalist

Oyedapo Oyekunle "Dapo" Olorunyomi (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kọkànlá ọdún 1957), jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdẹ̀ Naijiria. Òun ní olóòtú àgbà fún ìwé-ìròyìn Premiun Times[1][2] èyí tí ń ṣe ìwé-ìròyìn ti ilẹ̀ Nàìjíríà. Òun kan náà ni olùṣàkóso àgbà fún Premium Times fún Investigative Journalism (PTCIJ). Òun ni olùdarí fún Economic and Financial Crimes Commissin (EFCC).

Àtòjọ àwọn àmì-èyẹ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • International Editor of the Year Award (1995)
  • PEN Center (West) Freedom to Write Award (1996)
  • Press Freedom Award of the National Association of Black Journalists (NABJ)New York U.S.A (1996)
  • Hellman Hemmett grant of the Human Rights Watch (1996)
  • Diamond Award for Media Excellence's Lifetime Achievement Award by Diamond Publications (2017)[3][4][5]
  • CPJ International Press Freedom Awards (2021)

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Television, Channels. "Arrested Premium Times Publisher Released". www.channelstv.com. Channels Incorporated Limited. Retrieved 27 December 2020. 
  2. UNESCO (24 April 2018). "World Press Freedom Day 2018". www.en.unesco.org. UNESCO. Retrieved 27 December 2020. 
  3. Ezeamalu, Ben (6 December 2017). "PREMIUM TIMES' Publisher receives DAME Lifetime Achievement Award". The Premium Times, Nigeria.. https://www.premiumtimesng.com/news/top-news/251584-premium-times-publisher-receives-dame-lifetime-achievement-award.html. Retrieved 20 April 2019. 
  4. Premium Times, Centre for Investigative Journalism. "Member Dapo Olorunyomi". ptcij. Premium Times Centre for Investigative Journalism. Retrieved 20 April 2019. 
  5. IDOWU, LANRE. "Dapo Olorunyomi is 2017 Lifetime Awardee". Dame Awards. Dame Awards. Archived from the original on 20 April 2019. Retrieved 20 April 2019.