Femi Falana

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Femi Falana
Ọjọ́ìbí30 December 1958
Lagos State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́Lawyer
Àwọn ọmọ1

Fẹ́mi Fálànà SAN  (Senior Advocate of Nigeria) Jẹ́ agbẹjọ́rò àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ọmọ orílẹ̀ èdè̀ Nàìjíríà  tí wọ́n bí ní ọjọ́ Kẹẹ̀dógbọ̀n Oṣu Kejìlá, ọdún 1958.(30 December, 1958[citation needed]).[1] Ó díje dupò Gómìnà ní ìpínl̀ẹ Èkìtì ní ọdún 2007 ṣùgbọ́n ó pàdánù ìbò náà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú NCP (National Conscience Party) tí ó ti fìgbà kan jẹ́ Alága ẹgbẹ́ náà jákè-jádò Nàìjíríà ní ọdún 2011..[2]

Bákan náà, òun ni bàbá fún ọ̀kọrin, adẹ́rìín pòṣónú àti òṣèré orí ìtàgé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Falz.[3] Fẹ́mi jẹ́ ọkọ fún arábìnrin Fúnmi Fálànà tí òun náà tún jẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ní orílẹ̀ èd̀e Nàìjíríà.[4]

Àwọn ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Femi Falana". informationng.com. Retrieved December 1, 2015. 
  2. "Femi Falana". nigerianbiography.com. Retrieved December 1, 2015. 
  3. "My wife didn't like our son's music career –Femi Falana". The Punch. Archived from the original on August 24, 2015. Retrieved December 1, 2015. 
  4. Simeon Ndaji (5 August 2012). "Femi Falana left me at the mercy of judges – Funmi,wife". Vanguard News. http://www.vanguardngr.com/2012/08/femi-falana-left-me-at-the-mercy-of-judges-funmiwife/. Retrieved 21 June 2016.