Jump to content

Folashade Sherifat Jaji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Folashade Sherifat Jaji
Akápò ìjọba ìpínlè Èkó
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
30 May 2019
Lagos State Head of Service
In office
17 February 2015  26 October 2015
AsíwájúJosephine Oluseyi Williams
Arọ́pòOlabowale Ademola
Permanent Secretary, Lagos State Ministry of Establishments, Training and Pensions
AsíwájúTunji Bello
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí10 Oṣù Kẹta 1957 (1957-03-10) (ọmọ ọdún 69)
Surulere, Lagos State, Nigeria
Ẹgbẹ́ olóṣèlúNon-partisian

Folashade Sherifat Jaji (ti a bi ni ọjọ́ kẹta oṣù kẹta ọdun 1957) jé osise ìjoba ati akowe fun ijoba ìpínlè Eko.[1] O tún jé akowe fún ijoba Eko Lori eka to un ri soro owó fun awon osise ijoba to ti feyinti[2]. O ran ijoba orílè-èdè Nàìjirià lowo láti mu iyipada rere ba owó ti a fi pamo fún ilo awon osise ìjoba.

A bi Sherifat ni March 3, 1957 ni Surulere, ìpínlè Eko, orílè-èdè Naijiria. O lo ilé-ìwé primari ni ilé-ìwé Anglican Girls Primary to wa ni Surulere, Ìpínlè Eko koto dipe o lo si Queen's college ni Yaba, níbi to ti gba iwe eri WAEC ni odun 1974. O GBA àmì-èye Bachelor of Science ni Yinifasoti ìlú Ibadan, ko to dipe o lo sìrún ìlú(agubaniro) ni okan lara awon ile oti ní Naijiria.[3] O tun pada lo si Yunifasiti ìlú Eko fún àmì-èye master of business administration ni odun 1989.

Sherifat bèrè isé ijoba ni October 27, 1980 koto dipe o bere si un sise ni ofici Gomina ipinle Eko, o sise ni ofici Gomina fun odun meji(1980-1982), o ya si eka ise ijoba miran koto dipe o tun pada si un sise ni ofici Gomina fún odun meje(1985-1992)[4][5]

Ni March 1, 2011, o di akowe fun ijoba Eko ni eka to un ri si owo osise feyinti. Ni March 30 2019, a yan gegebi akowe gbogbogbo ijoba ipinle Eko

  1. "GOVERNOR BABAJIDE SANWO-OLU MAKES 1ST APPOINTMENT. NAMES MRS. FOLASHADE SHERIFAT JAJI, FORMER HEAD OF SERVICE AS SECRETARY TO THE STATE GOVERNMENT.". Lagos State Government. 2019-05-30. Archived from the original on 2019-05-31. Retrieved 2022-05-30.
  2. "Expert warns retirees on extravagancy". Newswatch Times. 2015-04-06. Archived from the original on 2016-07-03. Retrieved 2022-05-30. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2022-10-24. Retrieved 2022-05-30.
  4. "Sherifat Folashade Jaji Becomes Lagos Head of Service". Starconnect Media. 2015-02-20. Retrieved 2022-05-30.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  5. Times, Premium (2015-02-18). "Fashola swears in new Head of Service". Premium Times Nigeria. Retrieved 2022-05-30.