Glory Odiase

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Glory Odiase (ti a bi ni ọjọ karundinlogun oṣu Kẹsán odun 1993) jẹ awa kẹkẹ ọmọ orile-ede Naijiria . [1] O gba ami-eye goolu kan nigba ti o nsoju Naijiria ninu idije kẹkẹ gigun akoko idanwo ìdíje obinrin lẹgbẹẹ Ayọ Okafor, Rosemary Marcus, ati Gripa Tombrapa ni ere Gbogbo-Afirika ti ọdun 2015 ni Congo Brazzaville . [2]

Awọn itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Kazeem Busari (17 June 2013). "Ajibade wins Cyclefest Championship". The Punch. Archived on 20 June 2013. Error: If you specify |archivedate=, you must also specify |archiveurl=. http://www.punchng.com/sports/ajibade-wins-cyclefest-championship/. Retrieved 11 September 2015. 
  2. "All Africa Games: Team Nigeria women win gold in cycling". Vanguard. 10 September 2015. http://www.vanguardngr.com/2015/09/all-africa-games-team-nigeria-women-win-gold-in-cycling/. Retrieved 11 September 2015. 

Ita ìjápọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]