Grace Nortey
Ìrísí
| Grace Nortey | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | 1 Oṣù Kejì 1937 Ghana |
| Iṣẹ́ | Actress |
| Ìgbà iṣẹ́ | 1970s–present |
| Àwọn ọmọ | 5 |
Grace Nortey (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kìíní oṣù kejì ọdún 1937) jẹ́ òṣèrébìnrin ti orílẹ̀-èdè Ghana tó ti kópa nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ fíìmù àgbéléwò àti ti ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán.[1] Ó ti kópa nínú fíìmù àgbéléwò, eré orí-ìtàgé àti eré-oníṣe lóríṣiríṣi fún àádọ́ta ọdún, tí ó sì tún jẹ́ ọ̀kan lára àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ inú fíìmù àgbéléwò ti orílẹ̀-èdè Ghana. [2]
Ìgbésí ayé ara ẹni
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Nortey bí ọmọ márùn-ún. Òun sì ni ìyá Sheila Nortey tí òun náà jẹ́ òṣèré.
Àtòjọ àwọn fíìmù rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àwọn fíìmù
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]| Ọdún | Fíìmù | Ẹ̀dá-ìtàn | Ọ̀rọ̀ |
|---|---|---|---|
| 1985 | Nana Akoto | ||
| 1992 | The Other Side of the Rich | Mrs. Ampofo | |
| 2006 | Frozen Emotion | Direct-to-video | |
| 2008 | Before My Eyes | Wummi | Direct-to-video |
| 2011 | Sinking Sands | Grandma | |
| Ties That Bind | Church Member | ||
| 2015 | Beasts of No Nation | Old Witch Woman | |
| 2019 | P over D | Ayorkor | |
| '95 | Old Woman | ||
Àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- Best Cameo Actress (Movie: "Adams Apple") - Ghana Movie Awards (2011[3])
- Excellence in Arts - Glitz Women of the Year Honours (2016)
- Lifetime Achievement Award - Black Star International Film Festival (BSIFF) Awards (2018)
- Legendary Award for Outstanding Contributions: Ghana Actors Entertainment Award (GAEA) - (2020)
- Outstanding Contribution to Women's Excellence in The Performing Arts - 3Music Awards Women's Brunch (2021)
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Glitz top 100 inspirational women – Page 100 – Glitz Africa Magazine" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2021-05-26. Retrieved 2022-05-28.
- ↑ "Grace Nortey Marks 87th Birthday". DailyGuide Network. 2024-02-05. Retrieved 2024-08-19.
- ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; no text was provided for refs named:0