Hadiza Lantana Oboh

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Hadiza Lantana Oboh (ọdún 1959 sí 1998) jẹ́ awakọ̀ ojú òfuurufú ọmọ-orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Òun nìkan ni obìnrin tí ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi awakọ̀ ojú òfuurufú fún ilé ìṣẹ́ Nigeria Airways.[1] Wọ́n ṣekú pá ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kejì ọdún 1998, àwọn afunrasí nínú ọ̀rọ̀ náà jẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ nínú ilé rẹ̀ tí wón jà lólè.[2][3]

Ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Oboh ti ń wa ọkọ̀ òfuurufú fún ilé ìṣe míràn fún ọ̀pọ̀ ọdún kí ó tó bẹ̀rẹ̀ sí ń ṣiṣẹ́ fún ilé isẹ́ Nigeria Airways.[4]

Ikú rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Hadiza Lantana Oboh jẹ́ ọmọ ọdún kàndínlógójì nígbà tí wọ́n ṣekú pá.[2] Àwọn ọlọ́pá rí òkú rẹ̀ ní ihò tí wón da ìgbẹ́ sí lẹ́yìn tí wọ́n ká atọjú ọgbà rẹ̀ níbi tí ó ti ń gbìyànjú láti ta àwọn ǹkan ìní Hadiza. Àwọn ọlọ́pá gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ilé Hadiza kí wọ́n tó fi wọ́nlẹ̀ fún ìgbà díẹ̀. Àwọn òṣìṣẹ́ yí ṣálọ.[2][3]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Ijeoma Thomas-Odia, Celebrating ‘First Ladies’ of the professions, The Guardian, 23 March 2019. Accessed 16 May 2020.
  2. 2.0 2.1 2.2 Jo Daniel, The Tragic Story Of Captain Hadiza Lantana Oboh, Nigeria Airways’ First & Only Female Pilot, Information Nigeria, 20 June 2015. Accessed 16 May 2020.
  3. 3.0 3.1 Late Hadiza Lantana Oboh: Ex-Nigerian Airways pilot murdered in cold blood Archived 2020-06-15 at the Wayback Machine., Nigerian Flight Deck, 11 September 2016. Accessed 16 May 2020.
  4. West Africa, 1989, p.1922