Ijeoma Nwaogwugwu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Ijeoma Nwogwugwu jẹ́ òǹkọ̀ròyìn ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ olùdásílẹ̀ alákòóso ti Arise TV, tí ó jẹ́ ilé-iṣẹ́ ìròyìn ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn adarí ìwé-ìròyìn Thisday. Ó jẹ́ ayẹ̀ròyìn wò bákan náà ní ìwé-ìròyìn THISDAY.[2][3] Ó jẹ́ òǹkọ̀ròyìn-bìnrin kejì nínú ìtàn ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí wọ́n yàn gẹ́gẹ́ bíi ayẹ̀ròyìn wò ní ìwé-ìròyìn national, ènìyàn àkọ́kọ́ Doyin Abiola.[4]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ijeoma Nwogwugwu, Arise TV MD, named most powerful woman journalist in Nigeria". TheCable. May 30, 2020. 
  2. "In Nigerian Newspapers, Women Are Seen, Not Heard". Nieman Reports. 
  3. Nwabueze, Chinenye (10 February 2020). "30 Powerful Female Editors in Nigeria's Press History – MassMediaNG". 
  4. "Women's Day: Nigerian Women's Trailblazing Heels of Change". March 7, 2021.