Lagos Islanders

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Lagos islanders jẹ ẹgbẹ basketball ní Naijiria ti wón kalè sí ìpínlè Eko, ti a da ni ọdun 1984. Olorin Sound Sultan wà lara àwon to ni egbé Lagos Islanders lati ọdun 2014. Wọn Ma ún gbá ere boolu won pápá Idaraya Rowe Park ni agbegbe Yaba .

Ni odun 2016, wón kopa ninú ìdíje African Basketball League nitori Nigerian Basketball Federation(NBBF) ko dá won mo nigba náà, won fin òfin de won láti mó kopa nínú ìdíje abele[1] sùgbón a fagi lé ofin náà ní odun 2019.[2].

Awọn èye[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Premier League Naijiria

  • Awọn Nick jáwé olúborí ní (5): 1997, 1998, 1999, 2000, 2001

FIBA Africa Club Championship Cup

  • Won gbe ipò kẹta ni odun: 2000

Awọn itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Dstv Basketball: NBBF bans Warriors, Islanders, Union Bank". Vanguard News. March 14, 2016. Retrieved September 12, 2022. 
  2. Alao, Seyi (June 21, 2019). "NBBF Premier League commences on July 8". Latest Sports News In Nigeria. Retrieved September 12, 2022.