Jump to content

Moji Makanjuola

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

'Moji Makanjuolajẹ́ ògbóǹtarìgì nínú ìròyìn ṣíṣe àti agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1][2] Òun ni adarí tẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ́ àwọn oniroyin obìnrin ni Nàìjíríà (NAWOJ).[3][4]

Àkọ́lé àti ìṣẹ̀lẹ̀ iṣẹ́

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Moji Makanjuola, ọmọ ìlú Kwara State tí wọn bí sì ìlú náà, jẹ́ olújábọ̀ oníròyìn ìlera kan tó jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú àwọn oníròyìn amóhùnmáwòrán Nàìjíríà tó ti ṣe àfikún gidi sí ìdàgbàsókè àti ìmúlò ìròyìn journalism ní orílè èdè Nàìjíríà , pàápàá jùlọ nípa ìròyìn ìlera.[5]

Ó jẹ́ alábàáṣiṣẹ́pọ̀ ìbánisọ̀rọ̀ fún UN Women,[6] Tí ó sì tún ti ṣiṣẹ́ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ní Nigerian Television Authority (NTA) níbi tí ó ti gòkè sí ipò olórí ẹ̀ka ìlera àti akọ̀kọ obìnrin ṣáájú ìfẹ́yìnti rẹ. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ tí ó dangajia ní Center for Diseases Control, CDC AtlantaAmẹ́ríkà. [7]

Ṣáájú kí ó tó fẹ̀yíntì fi iṣẹ́ NTA sílẹ̀, ó ti fi ìgbà kan ṣiṣẹ́ ní National Television Broadcast, Kwara State, Nàìjíríà níbi tí ó ti jẹ́ alukoro àkọ́kọ́ tí ó kókó wá ní ilé isẹ́ tẹlifíṣọ̀n wọn.[8]

Makanjuola tún jẹ́ olórí Ẹ̀ka Ìfihàn àti Ìròyìn ti NTA láàárín ọdún 1980 sí ọdún 1985. Lẹ́yìn tí ó ti fi Nigeria Television Authority (NTA) sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olórí àkọ́kọ́ Ẹ̀ka Ìlera àti Ìbálòpọ̀ Obìnrin, ó tẹ̀síwájú láti máa ṣiṣẹ́ fún NTA lórí ìpinnu àdéhùn.[9] Makanjuola is also a cinematographer and the chief executive officer of Bronz and Onyx, an integrated marketing communications and strategy company.[8]

Ó jẹ́ Ààre èèkàn tí Nigerian Association of Women Journalists (NAWOJ).[8]'òun sì ni ó jé onkowe ìwé'Health Journalism: A Journey with Moji Makanjuola, Tí wọn tẹ jáde ní oṣù Kejìlá ọdún 2012.[10]Ní ọjọ́ okandinlogbon, oṣù kẹsàn-án, ọdún 2014, Aunty Moji, bí àwọn àwọn ènìyàn tí máa ń pe wọn, wá lára àwọn ọmọ orile-ede Nàìjíríà Márùn-ún lè ní ọdúnrún tí wọn gba àmì ẹ̀yẹ orile-ede làti owó Ààrẹ àná, Ààrẹ Goodluck Ebele Jonathan tí ilé Nàìjíríà . Wọn yàn gẹ́gẹ́ bí olórí fún National Health Insurance Authority (NHIA) Leadership Development Program on March 22, 2023.[11]

Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Order of the Federal Republic (MFR).[12] She is also an executive director of the International Society of Media in Public Health (ISMP).[13]

Wọ́n ráyè ròyìn wipé Makanjuola jẹ́ ẹni tí ó máa ń lo ọgbọ́n ìròyìn rẹ láti tọ́jú ìwòye àwọn tí kò ní ìgbàgbọ́ nínú àbísí ìtọ́jú àjàkálẹ̀-arun ní orílẹ̀-èdè náà. [14]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "Moji Makanjuola’s day of joy". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "New Telegraph – Service chiefs, eight governors, others make National Honours list". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. http://allafrica.com/stories/200702260564.html
  4. "Moji makanjuola: I never lied for government - The Sun News". The Sun News. Retrieved 30 September 2014.
  5. "First Lady pledges increased advocacy for women's health". Archived from the original on 30 September 2014. Retrieved 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  6. "Towards restoring peace in Northern Nigeria through women". Daily Independent, Nigerian Newspaper. Archived from the original on September 2, 2014. Retrieved 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. "The Challenge Judges – The African Story Challenge". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  8. 1 2 3 Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named "women-ruling-journalism".
  9. "The Challenge Judges - the African Story Challenge". Archived from the original on 2014-10-06. Retrieved 2014-10-06. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  10. "First Lady pledges increased advocacy for women's health | Royal Time…". Archived from the original on 30 September 2014. Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  11. II, Admin (2023-03-22). "Chief (Mrs) Moji Makanjuola Appointed Champion For NHIA - FOREFRONT NG Appointed, champion, Moji Makanjuola, NHIA". FOREFRONT NG (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2024-06-19.
  12. "A Memorable Night with Ace-Broadcaster, Anty Moji". 6 October 2016.
  13. "Bamigboye put me on career path – Moji Makanjuola".
  14. "How One Journalist Used Her Reporting Skills to Convert Vaccine Skeptics in Nigeria".