National Museum tí orílè-èdè Nàìjíríà

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Musiomu Orilẹ-ede Naijiria jẹ ile musiọmu ní ìpínlè Èkó, orílè-èdè Nàìjíríà Ile-išẹ musiọmu naa ni akojọpọ àwon ère ati aworan nlá ni Naijiria, pẹlu awọn awọn ohun-ọṣọ. [1] Musiomu náà wa ni Onikan, Lagos Island, Ipinle Eko. Ówà labé idari National Commission for Museums and Monuments.

Ọgbà níwájú Musíọ́mù orílẹ̀ èdè Nàìjíríà

Ìtàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Kenneth Murray dá Musiomu náà kalè ní odún 1957, a da Musiomu náà kalè láti jé ilé ipamo fún àwon ohun esó àti ohun àsà orílè-èdè Nàìjíríà.[2]

Àwon atojo òhun èsó[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Musiomu náà jé ilé fún àwon ohun esó àti àsà bi egbèrún metadinlagota, [3] àwon ohun àsà bi ibon, aso egungun, ìlù àti ere.

Ibi Àwòrán[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwon Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Nations Encyclopedia
  2. Board, Editorial (March 16, 2016). "Rehabilitating the National Museum - Nigeria and World News". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved September 10, 2022. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  3. "The National Museum of Lagos Six Enthralling Masterworks at the National". RefinedNG. October 9, 2021. Retrieved September 10, 2022.