Rita Orji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Rita orgi)

Rita Oluchi Orji jẹ́ ọmọ orílé-èdè Nàìjíríà, tí ó tún fi apá kan tan mọ́ Kánádà. Ó jẹ́ onímọ̀ kọ̀m̀pútà fún Kánádà nínú ìwádìí jinlẹ̀ fún ẹgbẹ́ pasuáfùù. Àti olùdarí pasuáfùù kòmpútí laàbù tí ilé ẹ̀kọ́ gíga yunifásítì Dalhousie. Ìṣe rẹ̀ dá lé lórí bí a ṣe lè lo ìṣòro ǹ gbésì láàrin ènìyàn àti ẹ̀rọ kọ̀m̀pútà.

Dókítà Rita Orji

Ó ti gbá àmì ẹ̀yẹ tó ti tó àádọ́rin, àti àmì ìdánimọ̀ ní agbègbè, àyíká àti àgbà-ń-lá-ayé. Ó sì tún ṣe iṣẹ́ pàtàkì nípa rírí sí àsíá àwọn obìnrin nínú ẹgbẹ́ Àjọ àwọn Orílẹ̀-èdè panel, tí ilé ìgbìmò asòfin Kánádà.