Ruth Osime

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ruth Osime
Ọjọ́ìbí7 Oṣù Kejì 1964 (1964-02-07) (ọmọ ọdún 60)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́Journalist, Editor
Parent(s)Chief Grace Osime (Mother)
Àwọn olùbátanGrace Osime, Omome Osime-Oloyede
WebsiteThisDay Style

Ruth Osime (tí a bí ní ọjọ́ keje osù kejì ọdún 1964) jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ́-èdè Nàìjíríà.[1] ó ti figba kan jẹ́ olóòtú ìwe THISDAY Style Magazine ri, ti o jẹ́ ìwé ìròyìn tí ó ní se pẹ̀lú oge síṣe.[2][3]

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ruth Osime ni ọmọ Chief Grace Osime, o si ni awọn àbúrò obìnrin méjì; Grace Osime àti Omome Osime-Oloyede.[4]

Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Isẹ́ ẹ Osime ní ilé-isẹ́ THISDAY bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olùdarí ètò ilé-isẹ́ náà, léyìn náà ló di ònkọ̀wé ati olóòtú àrà ní odún 2003, ipò tí ó dìmú títí di osù kẹrin ọdún 2022.[5]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Yaakugh, Kumashe (2021-03-10). "Who we offend? - Nigerian journalist reacts to 1976 receipt of N3,205 Honda car". Legit.ng - Nigeria news. (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-03-25. 
  2. Elites, The (2019-02-07). "Celebrating Ruth Osime, The Ultimate Style Connoisseur, At 55". The Elites Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-12-02. 
  3. "Ruth Osime sets Lagos aglow". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-02-24. Retrieved 2021-12-02. 
  4. Elites, The (2019-02-07). "Celebrating Ruth Osime, The Ultimate Style Connoisseur, At 55". The Elites Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-12-02. 
  5. "About Us". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2016-02-26. Retrieved 2021-12-02.