Sa'a Ibrahim

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Sa'a Ibrahim jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti òṣìṣẹ́ ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀. Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tó máa di alága Broadcasting Organisation of Nigeria (BON). Òun sì ni olùdarí àgbà fún ẹ̀rọ̀-amóhùn máwòrán ti Abubakar Rimi.[1][2]

Ìgbésí ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Hajia Sa'a Ibrahim ni wọ́n bí sínú ìdílé Malam Ibrahim àti Yalwa Bello ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹrin ọdún 1960 ní Magashi Quarters ní ìjọba ìbílẹ̀ Gwale ní ipinle Kano .

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Sa'a Ibrahim elected new BON chairman, becomes first female to lead since 1988". Daily Nigerian (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-10-23. Archived from the original on 2021-06-27. Retrieved 2021-06-29. 
  2. "Sa'a Ibrahim appointed MD of Kano TV". Retrieved 2021-07-02 – via PressReader.