St. Thomas Anglican Primary School, Badagry

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

St. Thomas Anglican Primary School jẹ́ ilé-ìwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ tí wọ́n dá sílẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nigeria lọ́dún 1845 ní ìlú Badagry, ní Ìpínlẹ̀ Èkó. Àlùfáà Rev. Golmer tí ìjọ Church Missionary Society (CMS) ni ó dá ilé-ìwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ St Thomas Anglican sílẹ̀ lọ́dún 1845. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé náà ni ibí tí ilé alájà àkọ́kọ́ wà ní Badagry. Ọ̀gbẹ́ni Philips ni olùkọ́ àti olùkọ́-àgbà àkọ́kọ́ ní ilé-ìwé náà láti ọdún 1845 sí 1867.[1]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "ST THOMAS PRIMARY SCHOOL, Badagry - Lagos Schools Online". Archived from the original on 2023-01-21. Retrieved 2023-01-21.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)