Tọ́lá Ọládòkun

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Ọwọ́mitọ́lá Oládòkun tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ìka lọmọ Ejò jẹ́ gbajú gbajà òṣèré orí-ìtàgé Yorùbá, ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Wọ́n bi ní ìlú Ìgàngàn tí ó jẹ ọ̀ was ọ̀kan lára àwọn ìlú Ìbàràpá méjèèjéÌpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.[1]Ó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti ti Girama ní Ilé-Ẹ̀kọ́ Methodist Primary School tí ó wà ní Ìlú Ìgàngàn. [2][3] [4]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "My husband once told me to choose between my career and home –Tola Oladokun – Punch Newspapers". Punch Newspapers – The most widely read newspaper in Nigeria. 2015-12-15. Retrieved 2019-12-12. 
  2. "WOMEN SHOULD KNOW HOW TO HANDLE MALE ADMIRERS WITH WISDOM - TOLA OLADOKUN". Modern Ghana. 2008-04-20. Retrieved 2019-12-12. 
  3. "Tola Oladokun". Nollywood Forever Movie Reviews. 2009-02-04. Archived from the original on 2019-04-20. Retrieved 2019-12-12. 
  4. "Veteran Actress,Tola Oladokun Signs Endorsement Deal With Property Company In Lagos". Yoruba Movie Gist TV. 2016-06-09. Archived from the original on 2019-08-17. Retrieved 2019-12-12.