Jump to content

Abubakar Tafawa Balewa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Tafawa Balewa)
Abubakar Tafawa Balewa
Alakoso Agba ile Nàìjíríà
In office
October 1, 1959  January 15, 1966
Arọ́pòNone
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1912
Bauchi, Nàìjíríà
Aláìsí15 January, 1966
Ẹgbẹ́ olóṣèlúNorthern People's Congress

Abubakar Tafawa Balewa (December 1912 – January 15, 1966) jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè e Nàìjíríà, láti apá àríwá ilẹ̀ Nàìjíríà[1]. Balewa jẹ́ Alákòóso Agba (prime minister) àkọ́kọ́ fún ilẹ̀ Nàìjíríà ní ìgbà òṣèlú àkọ́kọ́ ilẹ̀ Nàìjíríà lẹ́yìn ìgbà tí Nàìjíríà gba òmìnira ní ọdún-un 1960.[2] Ẹni àyẹ́sí ni kárí ayé, ó gba ọ̀wọ̀ ní orílẹ̀ Áfíríkà gẹ́gẹ́ bí ìkan lára àwọn n tí wọ́n dábàá dídá sílẹ̀ àkójọpọ̀ ẹgbẹ́ ìsọ̀kan ti Afrika (Organization of African Unity, OAU)[3].[4][5]

Ìgbà èwe àti iṣẹ́ ọwọ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]


  1. Faal, Courtney; Faal, Courtney (2009-05-09). "Sir Abubakar Tafawa Balewa (1912-1966) •". Welcome to Blackpast •. Retrieved 2023-06-20.
  2. "Sir Abubakar Tafawa Balewa". Encyclopedia Britannica. 1998-07-20. Retrieved 2023-06-12.
  3. "Abubakar Tafawa Balewa". New World Encyclopedia. 1959-10-01. Retrieved 2023-06-20.
  4. Nigeria, Guardian (2022-01-12). "Remembering Abubakar Tafawa Balewa, 56 years later". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved 2023-06-12.
  5. "Sir Abubakar Tafawa Balewa". Encyclopedia.com. 2023-05-25. Retrieved 2023-06-12.