Taiye Selasi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:Non-free

Taiye Selasi
Selasi at the Erlanger Poetenfest, 2013
Ọjọ́ ìbíTaiye Selasi
2 Oṣù Kọkànlá 1979 (1979-11-02) (ọmọ ọdún 44)
London, United Kingdom
Iṣẹ́Novelist
Alma materYale University; Nuffield College, Oxford
Ìgbà2005–present
Literary movementRealism, Drama
Website
Taiye Selasi lórí Twitter

Taiye Selasi (bíi ni ọjọ́ kẹji oṣù kọkànlá ọdún 1979) jẹ́ akọ̀wé àti ayàwòrán.[1][2]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Taiye sì ìlú London, òun sì ni àkọ́bí nínú ìbejì tí àwọn òbí rẹ bí.[3] [4]Ìyá rẹ̀, Dr. Juliette Tuakli, jẹ́ oníṣègùn ni orílẹ̀ èdè Ghana,[5][6] bàbà rẹ, Dr. Lade Wosornu, sì jẹ́ dókítà ni ilẹ̀ Saudi Arabia.[7][8][9] Taiye gboyè akẹ́kọ̀ọ́ to tayọ julọ ni Yale University. Ó tẹ̀ síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ gíga tí Nuffield College.[10]

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní ọdún 2005, ìwé ìròyìn tí The Lip ṣe atẹjade iṣẹ́ rẹ̀ tí ó pè àkòrí rẹ̀ ni Bye-Bye.[11][12][13][14] Ní ọdún 2006, ó kọ ìwé nípa àwọn ọmọbìnrin ni ilẹ̀ Áfríkà, ó sì pe àkòrí rẹ ni The Sex Lives of African Girls.[15] Ní ọdún 2010, Ann Godoff ra ìwé Taiye tí àkòrí rẹ jẹ Ghana must Go, ó sì ṣe atẹjade rẹ̀ ni ọdún 2013.[16][17][18][19][20][21][22] Ni ọdún 2013 àti 2014, wọn fi sì àárín àwọn akọ̀wé ọ̀dọ́ tí ó dára jù lọ.[23] Ni ọdún 2012, òun àti David Adjaye jọ ṣètò ilé ìkàwé tí Gwangju River Reading Room.[24] Ní ọdún 2015, Selasi farahàn sì ayẹyẹ tí wọn má ṣe fún àwọn òn kọ̀wé ni orílẹ̀ èdè Iceland, Iceland Writers Retreat, ó sì jẹ́ ìkan laarin awọn tó sọ̀rọ̀.[25]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Lewis, Tim (22 March 2013). "Taiye Selasi: 'I'm very willing to follow my imagination'". The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/books/2013/mar/22/taiye-selasi-interview-ghana-must. Retrieved 2019-03-27. 
  2. Selasi, Taiye (22 March 2013). "Taiye Selasi on discovering her pride in her African roots". The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/books/2013/mar/22/taiye-selasi-afropolitan-memoir. Retrieved 2019-03-27. 
  3. Virginia Vitzthum, "The Fascinator: Taiye Selasi", Elle, 15 March 2013.
  4. "Family matters: how novelist Taiye Selasi came to terms with her very modern family", London Evening Standard, 5 April 2013.
  5. "Dr. Juliette Tuakli, Child and Reproductive Health, University of Ghana, Legon.The Bill and Melinda Gates Institute for Population and Reproductive Health
  6. "Juliette Tuakli". Jhsph.edu. Archived from the original on 14 December 2012. Retrieved 31 March 2011.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. "Prof. Lade Wosornu" Archived 2017-05-21 at the Wayback Machine., University of Dammam.
  8. "Lade Wosornu". 9 September 2009. Retrieved 31 March 2011. 
  9. "Prof. Lade Wosornu Compiles His Articles into A Book". The Ghanaian Times. Archived from the original on 23 August 2011. https://web.archive.org/web/20110823060853/http://newtimes.com.gh/story/1165. Retrieved 31 March 2011. 
  10. "Taiye Selasi", Ghana Rising, 25 February 2012.
  11. Taiye Selasi, "Bye-Bye, Babar", The LIP Magazine, 3 March 2005.
  12. Bady, Aaron, and Taiye Selasi. "From That Stranded Place." Transition 117 (2015): 148. Web.
  13. Gehrmann, Susanne. "Cosmopolitanism With African Roots. Afropolitanism's Ambivalent Mobilities". Journal of African Cultural Studies 28.1 (2015): 61-72. Web.
  14. Stefanie Cohen, "Growing Up With a Panther Mom", The Wall Street Journal, 28 February 2013.
  15. "Interview: Taiye Selasi", Granta, 10 June 2011
  16. Diana Evans, "Ghana Must Go by Taiye Selasi – review", The Guardian, 3 April 2013.
  17. Margaret Busby, "Ghana Must Go, By Taiye Selasi" (review), The Independent, 29 March 2013.
  18. "A singular voice", The Economist, 16 March 2013.
  19. Sam Sacks, "An Auspicious How-Do-You-Do", The Wall Street Journal, 1 March 2013.
  20. Molly Fischer, "Penguin Press Buys First Novel with Salman and Toni’s Seal of Approval" Archived 2010-06-15 at the Wayback Machine., New York Observer, 14 June 2010.
  21. "The WSJ Best Fiction of 2013", The Wall Street Journal, 13 December 2013.
  22. "Books of the year: Torrents of words", The Economist, 5 December 2013.
  23. Granta 123: Best of Young British Novelists 4, Spring 2013.
  24. "david adjaye & taiye selasi: gwangju river reading room", designboom, 20 December 2013.
  25. "IWR 2015". Iceland Writers Retreat (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2016-06-07. Archived from the original on 2020-02-13. Retrieved 2020-02-13.