ThisDay
THISDAY jẹ́ òkan lara àwon iwe iroyin ní orilẹ-ede Naijiria. A tèé ìwé iroyin THISDAY jáde fún ìgbà akoko ni ọjọ 22 Oṣu Kini ọdun 1995(22 January 1995).[1] Olu ile-iṣẹ rẹ wà ni Apapa, ìpínlè Eko. Oludasile ilé-isé iroyin náà ni Nduka Obaigbena, òun ni alaga egbe THISDAY media ati ikanni Irohin ARISE.
THISDAY ni ilé-isé méta fún ìte iroyin, wón wà ní Abuja, Èkó àti Asaba, àwon ni ilé iwe-iroyin tí ó kókó lò inki aláwò ní Nàìjirià [2]
Àwon Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ "About Us". THISDAYLIVE. 2016-02-26. Retrieved 2022-04-29.
- ↑ Otufodunrin, Lekan; Network, Media Career Development; Adeniyi, Esther; Udom, Emmanuel; Development, Media Career (2020-02-10). "THISDAY @ 25: Success story, impact, low points". Media Career Services. Retrieved 2022-04-29.