Jump to content

This Day

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Àyọkà yìí jẹ mọ́ nípa the Nigerian newspaper. Fún ìtumọ́ míràn, ẹ wo: This Day (ìṣojútùú).
THISDAY
THISDAY LOGO.png
TypeDaily newspaper
FormatBroadsheet
OwnerNduka Obaigbena
PublisherLeaders & Company Ltd.
FoundedOṣù Kínní 22, 1995; ọdún 29 sẹ́yìn (1995-01-22)
LanguageEnglish
HeadquartersApapa, Lagos
Official websiteÀdàkọ:Official URL

This Day jẹ́ òkan lára àwon ìwé-ìròyìn olójoojúmọ́ ní orílẹ̀-èdè Naijiria.  A tẹ ìwé iroyin THISDAY jáde fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọjọ kejìlélógún oṣù kínní, ọdún 1995 (22 January 1995).[1] Olú iléeṣẹ́ rẹ̀ wà ní ilú Apapa, ní Ìpínlẹ̀ Èkó.  Olùdásílẹ̀ ilé-isé ìròyìn náà ni Nduka Obaigbena, òun ni alága ẹgbẹ́ THISDAY media àti ìkànnì ìròyìn ARISE.

THISDAY ni ilé-isé méta fún ìte iroyin, wón wà ní Abuja, Èkó àti Asaba, àwon ni ilé iwe-iroyin tí ó kókó lò inki aláwò ní Nàìjirià [2]

  1. "About Us". THISDAYLIVE. 2016-02-26. Retrieved 2022-04-29. 
  2. Otufodunrin, Lekan; Network, Media Career Development; Adeniyi, Esther; Udom, Emmanuel; Development, Media Career (2020-02-10). "THISDAY @ 25: Success story, impact, low points". Media Career Services. Retrieved 2022-04-29.