Tony Momoh

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Prince Tony Momoh
Minister of Information and Culture
In office
1986–1990
Arọ́pòAlex Akinyele
Chairman, Congress for Progressive Change
In office
January 2011 – 1 February 2021
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí(1939-04-27)27 Oṣù Kẹrin 1939
Auchi, Colonial Nigeria
Aláìsí1 February 2021(2021-02-01) (ọmọ ọdún 81)
Websitehttp://www.tonymomoh.com

Ọmọ oba Tony Momoh (tí a bí ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣu kẹrin ọdún 1939, tó sì kú ní ọjọ́ kínní oṣù kejì ọdún 2021)[1] jẹ́ akọ̀ròyìn Nàijíríà àti olóṣèlú kan tí ó jẹ́ Mínísítà fún Ìfitónilétí àti Àṣà Nàijíríà (láti ọdún 1986 wọ 1990) lákòókò ìjọba ológun ti Ọ̀gágun Ibrahim Babangida.

Ìbí àti ẹ̀kọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Momoh ní ọjọ́ 27 Oṣù Kẹrin ọdún 1939 ní Auchi, ìjọba ìpínlẹ̀ Edo. Ó jẹ́ ọmọ karùn-ún lé lọ́gọ́jọ (165) ti Ọba Momoh I ti Auchi.[2]

Ó lọ sí Ilé-ìwé Ìjọba Auchi (1949–1954) àti Ilé-ìwé Anglican Okpe (1954). Momoh jẹ́ Olùkọ́ni Akẹ́ẹ̀kọ́ ní Ilé-ìwé Anglican, Auchi (Oṣù kińní- Oṣù kejìlá 1955) ati Olukọni ni Ile-iwe Anglican, Ubuneke, Ivbiaro, Ijọba Ibile Owan (January 1958 - Kejìlá 1959).[3]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Iniobong, Iwok (1 February 2021). "Life and times of Tony Momoh". BusinessDay.ng. Archived from the original on 1 February 2021.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "OBITUARY: Tony Momoh, the 165th child of Edo monarch who defended Buhari till he died". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 February 2021. Retrieved 2021-07-09. 
  3. "Biography – Positions held before being a Journalist". Tony Momoh. Retrieved 18 June 2011.