Jump to content

Toyin Adewale-Gabriel

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Toyin Adewale-Gabriel
Ọjọ́ìbíToyin Adewale
1969 (ọmọ ọdún 5657)
Ibadan, Oyo State, Nigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaObafemi Awolowo University, Ile-Ife
Iṣẹ́Writer, novelist
Ìgbà iṣẹ́1995–present

Toyin Adewale-Gabriel (tí wọ́n bí ní ọdún un 1969)ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, jẹ́ òǹkọ̀wé ewì,ó sì ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí olùṣàyẹ̀wò ìwé fún The Guardian], Post Express àti The Daily Times.[1] Adewale-Gabriel le kọ̀wé ní èdè Gẹ̀ẹ́sì àti ní èdè Jámánì[2][3]

Ìtàn ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ìgbésí ayé ẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Toyin ní ìlú Ibadan, ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà .ó gba oyè MA Lit. láti ilé-ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì Obafemi Awolowo .[4] Ó si jẹ́ olùdásílẹ̀ àti olùdarí fún ọ̀pọ̀ ọdún nínú Ẹgbẹ́ Àwọn Òǹkọ̀wé ilẹ̀ Nàìjíríà.[1]

Iṣẹ́ Ìṣe rẹ̀

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn iṣẹ́ rẹ̀ ní Naked Testimonies(ẹ̀rí ìhòhò) 1995; Breaking The Silence (Dídá Ìdákẹ́rọ́rọ́ náà )1996; Inkwells, 1997; Die Aromaforscherin(iku aromaforscherin) 1998; Flackernde Kerzen, 1999; 25 New Nigerian Poets, 2000; Aci Cikolata, Gunizi Yayincilik, 2003; àti Nigerian Women Short Stories, 2005. Ó tún gba ẹ̀bùn fún ewì àti ìtàn àròsọ kúkúrú.[5] ati edekoyede kukuru.[4]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. 1 2 Aka, Jubril Olabode (2012). Nigerian Women of Distinction, Honour and Exemplary Presidential Qualities. Trafford. pp. 243. ISBN 9781466915541. https://books.google.com/books?id=A0I5gsKiDasC&q=%22Toyin+Adewale-Gabriel%22&pg=PA243.
  2. Oloruntoba-Oju, Taiwo (2009). "Tracking an African Feminist Aesthetic". In Barthet, Stella Borg. Shared Waters: Sounding in Postcolonial Literatures. Cross/Cultures. pp. 144–145. ISBN 9789042027664. https://books.google.com/books?id=Dq_pCUsFA0IC&q=%22Toyin+Adewale-Gabriel%22&pg=PA143.
  3. "Toyin Adewale Gabriel (Nigeria, 1969)". Festival Internacional de Poesía de Medellín. 28 June 2018.
  4. 1 2 Azuonye, Nnorom (November 2003). "Toyin Adewale-Gabriel". Sentinel Poetry (12). ISSN 1479-425X. http://www.sentinelpoetry.org.uk/magazine1103/page2.html. Retrieved 3 February 2016.
  5. Fandrych, Ingrid; Dunton, Chris (2002). "Toyin Adewale: A Preliminary Survey of Her Poetry and Fiction". English in Africa 29 (2): 85–99. ISSN 0376-8902. JSTOR 40238964. http://www.jstor.org/stable/40238964.