Tubokosemie Abere
Ìrísí
Tubokosemie Abere[1] (a bí i ní ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kẹjọ, ọdún 1950) jẹ́ olórí Àlùfáà ní ìjọ Anglican ní orílẹ̀-èdè Naijiria tí ó ti fẹ̀yìntì [2]. Ó jẹ́ olórí Àlùfáà ní Okrika, ọ̀kan nínú mẹ́sàn-án ìjọ Anglican ní ìgbèríko ti Niger Delta, ó sì jẹ́ ọ̀kan nínú mẹ́rìnlá nínú àwọn ìjọ Naijiria.[3]
Wọ́n yà á sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí aṣáájú Olórí Àlùfáà ní Okrika ní ìjọ St. Cyprian ti Port Harcourt ní ọjọ́ kẹrìndínlógún, oṣù kọkànlá, ọdún 2003,[4] o si gun ori alefa ni odun 2004.[5] O feyinti ni odun 2020.[6]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Office, Anglican Communion. "Anglican Communion: Diocese". Anglican Communion Website. Retrieved 2020-08-23.
- ↑ Ngozi Adighibe, 2019. Wike thankful for election victory as Abere charges christians to be grateful. The Guardian Newspaper. Available at: https://guardian.ng/sunday-magazine/wike-thankful-for-election-victory-as-abere-charges-christians-to-be-grateful/ Archived 2022-02-10 at the Wayback Machine. Accessed on 10 February 2022
- ↑ "Church of Nigeria news - latest breaking stories and top headlines". TODAY.
- ↑ acnntv. "Bishop Tubokosemie Abere: The Legacy Of A Missionary – A Tribute By Charles Ogan | Advent Cable Network Nigeria". Retrieved 2021-03-18.
- ↑ "PRESIDENTIAL ADDRESS/BISHOP'S CHARGE DELIVERED AT THE SECOND SESSION OF THE FOURTH SYNOD – DIOCESE OF NSUKKA, ON MONDAY 8 NO". webcache.googleusercontent.com. Retrieved 2021-03-18.
- ↑ "See Pictures Of The Best Bishop In Nigeria On His Retirement Service - Opera News" Archived 2022-02-10 at the Wayback Machine.. ng.opera.news. Retrieved 2021-03-08.