Tubokosemie Abere

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Tubokosemie Abere[1] (abi ni Ojo kejidinlogun Osu kejo Odun 1950) je Olori Alufa ni ijo Anglican ni Naijiria ti o ti feyinti[2]. O je Olori Alufa ni Okrika, ikan ninu mesan ijo Anglica ni igberiko ti Niger Delta, o si je ikan ninu merinla ninu ijo Naijiria.[3]

Won yaa soto gege bi asaaju Olori Alufa ni Okrika ni ijo St. Cyprian ti Port Harcourt ni ojo kerindinlogun osu kokanla odun 2003,[4] o si gun ori alefa ni odun 2004.[5] O feyinti ni odun 2020.[6]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Office, Anglican Communion. "Anglican Communion: Diocese". Anglican Communion Website. Retrieved 2020-08-23.
  2. Ngozi Adighibe, 2019. Wike thankful for election victory as Abere charges christians to be grateful. The Guardian Newspaper. Available at: https://guardian.ng/sunday-magazine/wike-thankful-for-election-victory-as-abere-charges-christians-to-be-grateful/ Accessed on 10 February 2022
  3. "Church of Nigeria news - latest breaking stories and top headlines". TODAY.
  4. acnntv. "Bishop Tubokosemie Abere: The Legacy Of A Missionary – A Tribute By Charles Ogan | Advent Cable Network Nigeria". Retrieved 2021-03-18.
  5. "PRESIDENTIAL ADDRESS/BISHOP'S CHARGE DELIVERED AT THE SECOND SESSION OF THE FOURTH SYNOD – DIOCESE OF NSUKKA, ON MONDAY 8 NO". webcache.googleusercontent.com. Retrieved 2021-03-18.
  6. "See Pictures Of The Best Bishop In Nigeria On His Retirement Service - Opera News" Archived 2022-02-10 at the Wayback Machine.. ng.opera.news. Retrieved 2021-03-08.