Yẹmí Àlàdé
Ìrísí
Yemi Alade | |
|---|---|
Yemi Alade | |
| Background information | |
| Orúkọ àbísọ | Yemi Eberechi Alade |
| Ọjọ́ìbí | 13 Oṣù Kẹta 1989 Abia State, Nigeria |
| Irú orin | |
| Occupation(s) |
|
| Instruments | Vocals |
| Years active | 2005–present |
| Labels |
|
| Associated acts |
|
| Website | yemialadeofficial.com |
Yẹmí Eberechi Àlàdé (ọjọ́ìbí 13 March 1989), tó gbajúmọ̀ pẹ̀lú orúkọ ìkọrin rẹ̀ bíi Yẹmí Àlàdé, ni akọrin Afropop omo orilede Nàìjíríà. Ó kọ́kọ́ gbajúmọ̀ nígbà tó gbẹ̀yẹ nínú ìdíje Peak Talent Show ní ọdún 2009, ó sì gbé àwo-orin rẹ̀ "Johnny" jáde ní ọdún 2014.[1][2][3] Bábá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Yoruba, ìyá rẹ̀ jẹ́ ará ẹ̀yà Igbo.[4]
Itokasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "New, sexy singers on the loose". vanguardngr.com. Retrieved 7 September 2014.
- ↑ "Yemi Alade tours Kenya". vanguardngr.com. Retrieved 7 September 2014.
- ↑ "My looks have helped my career –Yemi Alade". dailyindependentnig.com. Retrieved 7 September 2014.
- ↑ "How Yemi Alade Hustled Her Way To Become The Queen Of Afrobeats" (in en). The FADER. https://www.thefader.com/2016/11/09/yemi-alade-interview-tumbum-mama-africa.
[Ẹ̀ka:Àwọn ènìyàn alààyè]]
