Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ọsun State
Osun State
Flag of Osun State
Flag of Osun State
Flag of Ọsun State
Flag
Nickname(s): 
Location of Ọsun State in Nigeria
Location of Ọsun State in Nigeria
Country Nigeria
Date created27 August 1991
CapitalOsogbo
Government
 • GovernorGboyega Oyetola (APC)
 • Deputy GovernorBenedict Gboyega Alabi
 • LegislatureOsun State House of Assembly
Area
 • Total9,251 km2 (3,572 sq mi)
Area rank28th of 36
Population
 (1991 census)
 • Total2,203,016
 • Estimate 
(2005)
4,137,627
 • Rank17th of 36
 • Density240/km2 (620/sq mi)
GDP (PPP)
 • Year2007
 • Total$7.28 billion[1]
 • Per capita$2,076[1]
Time zoneUTC+01 (WAT)
ISO 3166 codeNG-OS
Websitehttps://www.osunstate.gov.ng

Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn Ìpínlẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun jẹ́ Ìpínlẹ̀ tí ó wà ní àárín gbùngbùn apá Ìwọ̀-Oòrùn Gúúsù orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Olú-ìlú rẹ̀ wà ní Ìlú Òṣogbo. Ó ní ibodè ní àríwá mọ́ Ipinle Kwara, ní ìlà-oòrùn díẹ̀ mọ́ Ipinle Ekiti àti díẹ̀ mọ́ Ipinle Ondo, ní gúúsù mọ́ Ipinle Ogun àti ní ìwọ̀oòrùn mọ́ Ipinle Oyo. Gómìnà ìpínlẹ̀ náà lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí ni Gómìnà Gboyega Oyetola .[2] Wọ́n dìbò yàn-án wọlé ní 2018.[3] Ọsun ní ibi tí ọ̀pọ̀ àwọn ibi mèremère tó gbajúmọ̀ wà. Ọgbà Yunifasiti Obafemi Awolowo to wa ni Ile-Ifẹ, ibi tó ṣe pàtàkì nínú àṣà Yorùbá. Àwọn ìlú tóṣe pàtàkì ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun tún ni Oke-Ila Orangun, Ila Orangun, Ede, Iwo, Ejigbo, Esa-Oke, Ìrágbìjí, Ada, Ikirun, Oke-Ila Orangun, Ipetu-Ijesha, Ijebu-Jesa, Erin Oke, Ipetumodu, Ibokun, Ode-Omu, Otan Ayegbaju, Ifetedo, Ilesa, Okuku, àti Otan-Ile. A da ipinle osun sile ni 27/08/1991.

Gboyega Oyetola ni gomina ipinle osun

Itan[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Osun river in Osogbo, Osun state

Ibi tí a ń pè ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun lo nii ni wọ́n da sileẹ̀ ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 1999. Wọ́ ṣe àfàyọ ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun láti ara Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ wọ́n fún Ìpínlẹ̀ náà ní orúkọ rẹ̀ látara omi Odò Ọ̀ṣun ìyẹn omi tí ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn òrìṣà ilẹ̀ Yorùbá.[4][5]

Ilé ẹ̀kọ́ gíga[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ijọba Ìbílẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Awọn ijọba íbílẹ̀ tí ó wà nì ìpínlẹ̀ Osun jẹ́ ọgbọ̀n. Awọn ná ní:

Ijọba Ìbílẹ̀ Olú ilé
Aiyedaade Gbongan
Aiyedire Ile Ogbo
Atakunmosa East Iperindo
Atakunmosa West Osu
Boluwaduro Otan Ayegbaju
Boripe Iragbiji
Ede North Oja Timi
Ede South Ede
Egbedore Awo
Ejigbo Ejigbo
Ife Central Ile-Ife
Ife East Oke-Ogbo
Ife North Ipetumodu
Ife South Ifetedo
Ifedayo Oke-Ila Orangun
Ifelodun Ikirun
Ila Ila Orangun
Ilesa East Ilesa
Ilesa West Ereja Square
Irepodun Ilobu
Irewole Ikire
Isokan Apomu
Iwo Iwo
Obokun Ibokun
Odo Otin Okuku
Ola Oluwa Bode Osi
Olorunda Igbonna, Osogbo
Oriade Ijebu-Jesa
Orolu Ifon Osun
Osogbo Osogbo

Àwọn èèyàn jànkànjànkàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "C-GIDD (Canback Global Income Distribution Database)". Canback Dangel. Retrieved 2008-08-20. 
  2. "Supreme Court affirms Gboyega Oyetola's election as Osun Governor". Premium Times Nigeria. 2019-07-05. Retrieved 2019-09-18. 
  3. "Appeal Court say Oyetola win Osun election". BBC News Pidgin. 2019-05-09. Retrieved 2019-09-18. 
  4. "Osun-Osogbo", Wikipedia (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì), 2020-04-27, retrieved 2020-06-10 
  5. "Osun-Osogbo", Wikipedia (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì), 2020-04-27, retrieved 2020-06-10 
  6. "FEDERAL COLLEGE OF EDUCATION IWO – IWO, OSUN STATE" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 29 August 2022. 
  7. "Management – Federal University of Health Sciences, Ila-Orangun" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 29 August 2022. 
  8. "RCCG Miracle Center | History". www.rccgmunich.com. Retrieved 10 April 2022. 
  9. "Remembering the thunderking of theatre, Duro Ladipo". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 7 March 2018. Retrieved 10 April 2022. 
  10. "Remembering one of Nigeria's pioneer comedians, Gbenga 'Funwotan' Adeboye". Nigerian Entertainment Today (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 1 May 2014. Retrieved 10 April 2022. 
  11. "Yoruba actress, Toyin Adegbola, appointed government official | Premium Times Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 5 August 2013. Retrieved 10 April 2022. 
  12. Àdàkọ:Cite ODNB
  13. admin (30 April 2017). "Isiaka Adeleke: The Death that Stunned Osun". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 10 April 2022. 
  14. "Akande and his hidden treasures". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 December 2021. Retrieved 10 April 2022. 
  15. "General Akinrinade @ 80". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 3 October 2019. Retrieved 11 April 2022. 
  16. "Akinyemi and the loneliness of exile". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 6 January 2022. Retrieved 11 April 2022. 
  17. "Bolaji Amusan (Mr Latin): actor, comedian loved by fans | Newswatch Times". web.archive.org. 2016-03-04. Archived from the original on 2016-03-04. Retrieved 2022-10-14. 
  18. "I’m a self-development junkie— Olusola Amusan". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-09-03. Retrieved 2022-10-14. 
  19. "Mr Rauf Aregbesola, what goes around, comes around". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 20 February 2022. Retrieved 11 April 2022. 
  20. "My encounter with bead painting - Lanre Buraimoh". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 5 June 2013. Retrieved 11 April 2022. 
  21. "Osun 2022: I'm fighting for my state, Davido defends support for uncle, Adeleke". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 16 March 2022. Retrieved 11 April 2022. 
  22. "Patricia Etteh: The fall and the triumph". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 25 April 2016. Retrieved 11 April 2022. 
  23. "Daddy Freeze don beg Oyedepo for forgiveness". BBC News Pidgin. https://www.bbc.com/pidgin/world-54136209. 
  24. "11 things you probably didn't know about Bola Ige". The Nation Newspaper (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 23 December 2021. Retrieved 11 April 2022. 
  25. Adelegan, Femi. (2013). Nigeria's Leading Lights of the Gospel: Revolutionaries in Worldwide Christianity. Westbow Press. p. 71. Retrieved 7 September 2019. ISBN 978-1449769543.
  26. Komolafe, Sunday Jide. (2013). The Transformation of African Christianity: Development and Change in the Nigerian Church. Langham Monographs, p. 107. Retrieved 7 September 2019. ISBN 978-1-907713-59-0.
  27. admin (18 December 2016). "Beyond Politics: Iyiola Omisore, an Accomplished Professional, Family Man". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 11 April 2022. 
  28. "You're a liar, not prudent, Oyinlola replies Akande | Premium Times Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 16 December 2021. Retrieved 11 April 2022.