Bọ́lá Ọdẹlékè

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Bọ́lá Ọdẹlékè
Ọjọ́ìbíỌdún 1950
Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́Nàìjíríà
Orílẹ̀-èdèNàìjíríà
Ọmọ orílẹ̀-èdèỌmọ Nàìjíríà
Iṣẹ́Evangelist
Ìgbà iṣẹ́1977–present

Bọ́lá Ọdẹlékè tí wọ́n bí lọ́dún 1850 jẹ́ òjíṣẹ́ Ọlọ́run, Ajíyìnrere Nàìjíríà àti Bíṣọ́ọ̀bù obìnrin àkọ́kọ́ ní Áfíríkà. Òun ni olùdásílẹ̀ ìjọ Power Pentecostal Church.[1][2]

Ìgbà èwe rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdẹlékè jẹ́ ọmọ bíbí ìlú Ìbàdàn, ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[3] Ó kàwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ àti ipele kejì ní IléṣàÌpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, ìlú màmá tó bí i lọ́mọ.[4] Ó di onígbàgbọ́ ọmọlẹ́yìn Jésù lọ́dún 1970,ṣùgbọ́n ọdún 1974 ló bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìyìnréré, tí ó sìn ṣe àjọyọ̀ ogójì ọdún tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Ọlọ́run lọ́dún 2014.[5] Ó gboyè Bíṣọ́ọ̀bù lọ́dún 1995,òun sìn ní Bíṣọ́ọ̀bù obìnrin àkọ́kọ́ ní ilẹ̀ Áfíríkà.[6]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "A woman shouldn't be a sex object—Bola Odeleke". Vanguard News. Retrieved 28 February 2015. 
  2. "Bling Bling Bishop, Bola Odeleke Pursues Tenants With OPC - Global News". globalnewsnig.com. Archived from the original on 27 February 2015. Retrieved 28 February 2015. 
  3. Paul Ukpabio. "My regret: ….not believing God as much as I ought to". thenationonlineng.net. Retrieved 28 February 2015. 
  4. "Now, I tell widows to mourn their husbands very well –Evangelist Bola Odeleke". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 10 March 2015. Retrieved 28 February 2015.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  5. KAYODE ALFRED. "Bishop Bola Odeleke in the news". thenationonlineng.net. Retrieved 28 February 2015. 
  6. "Bishop Bola Odeleke: My experience with men - churchtimesnigeria.org". churchtimesnigeria.org. Archived from the original on 27 February 2015. Retrieved 28 February 2015.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)