Last Flight to Abuja

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Last Flight to Abuja
AdaríObi Emelonye
Olùgbékalẹ̀
  • Obi Emelonye
  • Charles Thompson
Òǹkọ̀wé
  • Tunde Babalola
  • Obi Emelonye
  • Amaka Obi-Emelonye
Àwọn òṣèré
OrinLuke Corradine
Ìyàwòrán sinimáJames M. Costello
OlóòtúBen Nugent
Ilé-iṣẹ́ fíìmùNollywood Film Factory
OlùpínNetflix
Déètì àgbéjáde
  • 29 Oṣù Kẹfà 2012 (2012-06-29) (UK )
  • 3 Oṣù Kẹjọ 2012 (2012-08-03) (Nigeria)
Àkókò81 min
Orílẹ̀-èdèNigeria
ÈdèEnglish
Ìnáwó₦40 million[1]
Owó àrígbàwọlé₦57,050,000 (domestic gross)[1]

Last Flight to Abuja jẹ́ fíìmù 2012 Nàìjíríà àjálù tí a kọ nípasẹ̀ Tunde Babalola, tí Obi Emelonye ṣe àti mú jáde, tí Omotola Jalade Ekeinde, Hakeem Kae-Kazim àti Jim Iyke ṣe. Tí a yàwòrán ní Ìlú Èkó, fíìmù náà gba àwọn yíyan àbùn márùn-ún ní ọdún 2013 Africa Movie Academy Awards, tí ó borí ní ẹ̀ka “Fíìmù tí ó dára jùlọ nípasẹ̀ orísun Áfíríkà kan ní ilẹ̀ òkèèrè”. [2][3][4] Ní ọjọ́ márùn-dín-lógún, oṣù kẹfà ọdún 2020, 'Last Flight to Abuja' bẹ̀rẹ̀ àfihàn lórí Netflix ní ọdún mẹ́jọ lẹ́hìn tí ó kọ́kọ́ ṣe àfihàn ní Ìlú Lọ́ndọ́nù. [5]

Àwọn Òṣèré[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ṣíṣe Rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní àsìkò tí ó ń ṣiṣẹ́ fíìmù yìí, Emelonye ní láti bá àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀, àwọn ilẹ́-ìfowópamọ́, àti àwọn òṣìṣẹ́ aláṣẹ wọ̀ ní pápá-ọkọ̀ òfurufú Murtala Muhammed tó wà nílùú Èkó.[6]

Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 Kay, Chris (13 August 2013). "Moviemakers Beg Banks for Cash as Nollywood Goes Global". Bloomberg. https://www.bloomberg.com/news/2013-08-12/moviemakers-beg-banks-for-cash-as-nollywood-goes-global.html. 
  2. Arogundade, Funsho (16 March 2013). "Emelonye's ' Last Flight To Abuja' Tops AMAA Nominations". P.M. News Nigeria. http://pmnewsnigeria.com/2013/03/16/emelonyes-last-flight-to-abuja-tops-amaa-nominations. 
  3. "Africa Movie Academy Awards (AMAA) Winners 2013". Africa Movie Academy Awards. Archived from the original on 31 May 2013. Retrieved 2 June 2013.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  4. "Full List of Nominees for 2013 Africa Movie Academy Awards". African Spotlight (Lagos, Nigeria). 18 March 2013. Archived from the original on 7 November 2016. https://web.archive.org/web/20161107155015/http://africanspotlight.com/2013/03/18/full-list-of-nominees-for-2013-african-movie-academy-awards/. 
  5. "Obi Emelonye talks lessons from making Nollywood classics [Pulse Interview"]. http://www.pulse.ng/entertainment/movies/obi-emelonye-talks-lessons-from-making-nollywood-classics-pulse-interview/dfdg5fq/2020/03/18/. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  6. Kay, Chris; Spillane, Chris (13 December 2013). "Nollywood comes of age". Oman Tribune. Archived from the original on 13 December 2013. Retrieved 25 May 2019.