Olubunmi Olateru Olagbegi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Olubunmi Olateru Olagbegi
Ọjọ́ìbíIle-Ife, Oyo State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • Lawyer
  • Educationist
  • Jury
Ìgbà iṣẹ́1973 - Present
Àwọn olùbátan
Folagbade Olateru Olagbegi III brother
AwardsOFR

Olubunmi Olateru Olagbegi, OFR jẹ́ ọmọ ilé-ìgbìmọ̀ Nàìjíríà àti adájọ́ àgbà tẹ́lẹ̀ ti Ìpínlẹ̀ Ondo, Nàìjíríà. Ó tún jẹ́ olùkàwé ní Yunifásítì Afe Babalola. [1]

Ẹgbẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ Ayé Rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìdílé Omitowoju ní Ilé-Ifẹ̀, ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ni wọ́n bí Adájọ́ Olubunmi. Ìyàwó sínú ìdílé Ọlágbẹ́gi, ìdílé ọba ní Ọ̀wọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo, Nàìjíríà. Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì ti London níbi tí ó ti gba ìwé ẹ̀rí àti oye òye iṣẹ́ Òfin. Ní ọdún 1990, wọn yàn án sí ibùjókòó ti Adájọ́ ilé-ẹjọ́ gíga kan ti Ìdájọ́ Ìpínlẹ̀ Ondo àti ní ọdún 2003, ó di adájọ́ àgbà ti adájọ́ ìpínlẹ̀ náà. Ọdún méje ló ṣiṣẹ́ yìí kó tó di pé ó fẹ̀yìntì iṣẹ́ náà ní ọjọ́ kẹrin-dín-lọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdún 2010. Ní ọjọ́ kejì-dín-lọ́gbọ̀n oṣù kejìlá ọdún 2008 ni Olóyè Olusegun Obasanjo, Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà náà fún un ní ọlá ti orílẹ̀-èdè. [1]

Àwọn Ìtọ́ka Sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "Gladys Olumbuni Olateru Olegbegi". Afe Babalola University. Archived from the original on 4 March 2016. Retrieved 16 April 2016.