Òrìṣà Vlekete

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Òrìṣà Vlekete jẹ́ òrìṣà omi-òkun àwọn ẹ̀yà Ògù ní ìlú Àgbádárìgì tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Badagryìpínlẹ̀ Èkó lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Ojúbọ òrìṣà yìí wà ní ibi kan ni ìlú náà tí wọ́n ń pè ní Ojúbọ Vlekete, Ojúbọ yìí ni wọ́n fi sọ orúkọ ọjà ẹrú náà tí wọ́n ń pè ní ọjà Vlekete ni Àgbádárìgì. Ọjà Vlekete jẹ́ ọjà ẹrú tó tóbi jù lọ ní ilẹ̀ Áfíríkà. [1] [2]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Dioka, L.C. (2001). Lagos and Its Environs. First Academic. ISBN 978-978-34902-5-3. https://books.google.com/books?id=9pUPAQAAMAAJ. Retrieved 2019-11-30. 
  2. Fadipe, A.S.; Unesco (2000) (in fr). Commerce D'esclaves Et la Civilisation Occidentale À Badagry. Media Ace. ISBN 978-978-33660-3-9. https://books.google.com/books?id=D5UPAQAAMAAJ. Retrieved 2019-11-30.